ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w11 5/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:
  • Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá A Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
w11 5/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

May 15, 2011

Ẹ̀dà Tó Wà Fún Ìkẹ́kọ̀ọ́

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ TÁ A MÁA KẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ Ọ̀SẸ̀:

June 27, 2011–July 3, 2011

Ẹ̀yin Ìdílé Kristẹni—“Ẹ Wà Lójúfò”

OJÚ ÌWÉ 7

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 69, 57

July 4-10, 2011

Ẹ̀yin Ìdílé Kristẹni—“Ẹ Wà Ní Ìmúratán”

OJÚ ÌWÉ 11

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 32, 63

July 11-17, 2011

Ta Ló Ṣe Pàtàkì Jù Lọ ní Ìgbésí Ayé Rẹ?

OJÚ ÌWÉ 16

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 51, 49

July 18-24, 2011

‘Ìjìnlẹ̀ Ọgbọ́n Ọlọ́run Mà Pọ̀ O!’

OJÚ ÌWÉ 21

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 95, 116

July 25-31, 2011

Ìgbọ́kànlé Kíkún Nínú Jèhófà Ń Mú Ká Ní Ìgboyà

OJÚ ÌWÉ 28

ÀWỌN ORIN TÍ A Ó KỌ: 46, 23

Ohun Táwọn Àpilẹ̀kọ Tá A Máa Kẹ́kọ̀ọ́ Dá Lé

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 1, 2 OJÚ ÌWÉ 7 sí 15

Nínú àpilẹ̀kọ àkọ́kọ́, a jíròrò ojúṣe tí ẹnì kọ̀ọ̀kan nínú ìdílé Kristẹni ní kó lè rí i pé òun wà lójúfò nípa tẹ̀mí. Àpilẹ̀kọ kejì ṣàgbéyẹ̀wò bí jíjẹ́ kí ojú wa mú ọ̀nà kan, níní àwọn àfojúsùn tẹ̀mí àti ṣíṣe Ìjọsìn Ìdílé ti ṣe pàtàkì tó fún mímú kí gbogbo àwọn tó wà nínú ìdílé ní àjọṣe rere pẹ̀lú Ọlọ́run.

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 3 OJÚ ÌWÉ 16 sí 20

Jèhófà ló gbọ́dọ̀ ṣe pàtàkì jù lọ nínú ìgbésí ayé àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀. Àpilẹ̀kọ yìí sọ ẹ̀kọ́ tá a rí kọ́ nípa bó ṣe yẹ kí Jèhófà ṣe pàtàkì sí wa tó látinú ohun tó ṣẹlẹ̀ sí Éfà obìnrin àkọ́kọ́; Jóòbù ọkùnrin olóòótọ́ náà; àti Jésù Kristi, Ọmọ Ọlọ́run tó jẹ́ ẹni pípé.

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 4 OJÚ ÌWÉ 21 sí 25

Nínú Róòmù orí 11, àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù sọ̀rọ̀ nípa igi ólífì ìṣàpẹẹrẹ. Kí ni apá ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lára igi náà dúró fún? Bí a ó ṣe máa ṣe àyẹ̀wò ohun tí wọ́n dúró fún nínú àpilẹ̀kọ yìí, a máa lóye ohun púpọ̀ sí i nípa ète Jèhófà. Yàtọ̀ sí ìyẹn, bí ọgbọ́n Ọlọ́run ṣe jinlẹ̀ tó máa jẹ́ ìyàlẹ́nu fún wa.

ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ 5 OJÚ ÌWÉ 28 sí 32

Nínú àpilẹ̀kọ yìí, a jíròrò Sáàmù Kẹta àti Ìkẹrin, èyí tí Dáfídì Ọba kọ. Àwọn orin tí Ọlọ́run mí sí yìí fi hàn pé bá a bá ń gbàdúrà pé kí Jèhófà ràn wá lọ́wọ́ tá a sì ní ìgbọ́kànlé kíkún nínú rẹ̀ a ó lè máa lo ìgboyà. Ohun tí Dáfídì ṣe nìyẹn nígbà tí ìwà àdàkàdekè, irú èyí tí ọmọ rẹ̀ Ábúsálómù hù, kó ìdààmú bá a.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ

3 Ṣé O Máa Ń Gbádùn Kíkẹ́kọ̀ọ́ Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run?

6 “Alábòójútó Rere àti Ọ̀rẹ́ Wa Ọ̀wọ́n”

26 Bá A Ṣe Lè Máa Tọ Kristi Aṣáájú Pípé Náà Lẹ́yìn

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́