ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w13 1/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
  • Ìsọ̀rí
  • Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
w13 1/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

January 15, 2013

© 2013 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania..

Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

FEBRUARY 25, 2013–MARCH 3, 2013

Jẹ́ Onígboyà, Jèhófà Wà Pẹ̀lú Rẹ!

OJÚ ÌWÉ 7 • ORIN:60, 23

MARCH 4-10, 2013

Má Ṣe Jẹ́ Kí Ohunkóhun Mú Ẹ Jìnnà sí Jèhófà

OJÚ ÌWÉ 12 • ORIN: 106, 51

MARCH 11-17, 2013

Túbọ̀ Sún Mọ́ Jèhófà

OJÚ ÌWÉ 17 • ORIN: 52, 65

MARCH 18-24, 2013

O Lè Sin Jèhófà Kó O Má sì Kábàámọ̀

OJÚ ÌWÉ 22 • ORIN: 91, 39

MARCH 25-31, 2013

Àwọn Alàgbà Jẹ́ ‘Alábàáṣiṣẹ́pọ̀ fún Ìdùnnú Wa’

OJÚ ÌWÉ 27 • ORIN: 123, 53

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

▪ Jẹ́ Onígboyà, Jèhófà Wà Pẹ̀lú Rẹ!

Bíbélì sọ fún wa nípa ọ̀pọ̀ àwọn ìránṣẹ́ Jèhófà tí wọ́n ní ìgbàgbọ́ àti ìgboyà. Ìrírí wọn máa fún ìgbàgbọ́ wa lókun, ó sì máa jẹ́ kí àwa náà máa fi ìgboyà sin Jèhófà. Nínú àpilẹ̀kọ yìí la ti máa jíròrò ọ̀rọ̀ ẹsẹ Ìwé Mímọ́ wa ti ọdún 2013.

▪ Má Ṣe Jẹ́ Kí Ohunkóhun Mú Ẹ Jìnnà sí Jèhófà

▪ Túbọ̀ Sún Mọ́ Jèhófà

Ọ̀pọ̀ nǹkan ló wà láyé yìí tí a kò lè fi ọwọ́ ara wa yàn. Lára wọn ni àwọn òbí wa, ẹ̀gbọ́n tàbí àbúrò wa àti ibi tí wọ́n máa bí wa sí. Ṣùgbọ́n a lè yàn bóyá a máa sún mọ́ Ọlọ́run tàbí a máa jìnnà sí i. Nínú àwọn àpilẹ̀kọ yìí, a máa jíròrò ohun méje tí a kò gbọ́dọ̀ jẹ́ kó mú wa jìnnà sí Jèhófà.

▪ O Lè Sin Jèhófà Kó O Má sì Kábàámọ̀

Gbogbo wa la ti kábàámọ̀ rí, tó sì ṣe wá bíi pé ká ṣàtúnṣe àwọn ohun kan tá a ti ṣe kọjá. Àmọ́, tá a bá ń ṣàníyàn jù nípa àwọn àṣìṣe wa, kò ní ṣeé ṣe fún wa láti fi iṣẹ́ ìsìn Ọlọ́run sí ipò àkọ́kọ́. Nínú àpilẹ̀kọ yìí, a máa rí bí àpẹẹrẹ àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù ṣe lè ràn wá lọ́wọ́ láti sin Jèhófà ká má sì kábàámọ̀.

▪ Àwọn Alàgbà Jẹ́ ‘Alábàáṣiṣẹ́pọ̀ fún Ìdùnnú Wa’

Pọ́ọ̀lù sọ nínú lẹ́tà kejì tó kọ sí àwọn Kristẹni tó wà ní Kọ́ríńtì pé òun àtàwọn táwọn jọ ń ṣiṣẹ́ pọ̀ jẹ́ ‘alábàáṣiṣẹ́pọ̀ fún ìdùnnú wọn.’ (2 Kọ́r. 1:24) Kí làwọn alàgbà lè rí kọ́ látinú gbólóhùn yìí? Báwo la sì ṣe lè máa ran ara wa lọ́wọ́ ká lè máa bá a nìṣó láti fayọ̀ sin Ọlọ́run? A máa dáhùn àwọn ìbéèrè yìí nínú àpilẹ̀kọ yìí.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ

3 Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn Tinútinú—Ní Norway

32 Ọmọbìnrin Kan Lo Ìdánúṣe

ÀWÒRÁN Ẹ̀YÌN ÌWÉ: Tọkọtaya kan tó ti fẹ̀yìn tì lẹ́nu iṣẹ́ ń kọ́ ẹnì kan lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì ní iwájú ilé kan ní Àgọ́ Perrin. Bíi ti tọkọtaya yìí, àwọn ọmọ ìlú Haiti kan tí wọ́n ń gbé lókè òkun ti ń pa dà sí orílẹ̀-èdè wọn kí wọ́n lè lọ máa wàásù níbi tí wọ́n ti nílò àwọn oníwàásù púpọ̀ sí i

HAITI

IYE ÈÈYÀN TÍ AKÉDE KAN Á WÀÁSÙ FÚN NÍ HAITI

1:557

IYE AKÉDE

17,954

ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ BÍBÉLÌ

35,735

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́