ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w14 4/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2014
  • Ìsọ̀rí
  • Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2014
w14 4/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

April 15, 2014

© 2014 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania

Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

JUNE 2-8, 2014

Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Ìgbàgbọ́ Mósè

OJÚ ÌWÉ 3 • ORIN: 33, 133

JUNE 9-15, 2014

Ǹjẹ́ Ò Ń Rí “Ẹni Tí A Kò Lè Rí”?

OJÚ ÌWÉ 8 • ORIN: 81, 132

JUNE 16-22, 2014

Kò Sí Ẹni Tó Lè Sin Ọ̀gá Méjì

OJÚ ÌWÉ 17 • ORIN: 62, 106

JUNE 23-29, 2014

Jẹ́ Onígboyà —Jèhófà Ni Olùrànlọ́wọ́ Rẹ!

OJÚ ÌWÉ 22 • ORIN: 22, 95

JUNE 30, 2014–JULY 6, 2014

Ǹjẹ́ O Mọyì Bí Jèhófà Ṣe Ń Fìfẹ́ Ṣọ́ Wa?

OJÚ ÌWÉ 27 • ORIN: 69, 120

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

▪ Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Ìgbàgbọ́ Mósè

▪ Ǹjẹ́ Ò Ń Rí “Ẹni Tí A Kò Lè Rí”?

Ìgbàgbọ́ tí Mósè ní mú kó máa rí ohun tó kọjá èyí tó lè fi ojú lásán rí. Nínú àpilẹ̀kọ yìí, a máa jíròrò bá a ṣe lè lo ìgbàgbọ́ bíi ti Mósè ká sì máa bá a lọ ní “fífẹsẹ̀múlẹ̀ ṣinṣin bí ẹni tí ń rí Ẹni tí a kò lè rí.”—Héb. 11:27.

▪ Kò Sí Ẹni Tó Lè Sin Ọ̀gá Méjì

▪ Jẹ́ Onígboyà—Jèhófà Ni Olùrànlọ́wọ́ Rẹ!

Àràádọ́ta ọ̀kẹ́ èèyàn kárí ayé ti yàn láti fi ìlú ìbílẹ̀ wọn sílẹ̀ kí wọ́n lè wá iṣẹ́ lọ sí ilẹ̀ òkèèrè. Ọ̀pọ̀ lára wọn ló sì fi ìyàwó àtàwọn ọmọ sílẹ̀ nílé. Àwọn àpilẹ̀kọ yìí máa jẹ́ ká mọ ojú tí Jèhófà fẹ́ ká máa fi wo ojúṣe wa nínú ìdílé, ó sì tún máa jẹ́ ká mọ bí Jèhófà ṣe ń ràn wá lọ́wọ́ láti ṣe ojúṣe náà.

▪ Ǹjẹ́ O Mọyì Bí Jèhófà Ṣe Ń Fìfẹ́ Ṣọ́ Wa?

Nígbà tá a bá kà á nínú Bíbélì pé “ojú Jèhófà ń bẹ ní ibi gbogbo,” àwọn kan lára wa lè máa rò pé ohun tó jẹ Ọlọ́run lógún ni bó ṣe máa rí sí i pé à ń pa àwọn òfin òun mọ́. Ìyẹn sì lè mú ká máa ní ìbẹ̀rù tí kò tọ́. (Òwe 15:3) Àmọ́, àpilẹ̀kọ yìí máa jẹ́ ká rí ọ̀nà márùn-ún tá a lè gbà jàǹfààní látinú bí Jèhófà ṣe ń fìfẹ́ bójú tó wa.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ

13 Ibi Tí Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Alákòókò Kíkún Gbé Mi Dé

32 Ǹjẹ́ O Mọ̀?

ÀWÒRÁN IWÁJÚ ÌWÉ: Ní ìlú Istanbul arákùnrin kan ń wàásù lọ́nà àìjẹ́ bí àṣà fún ẹni tó máa ń gẹrun fún un, ó ń fún un ní ìwé Ìròyìn Ayọ̀ Látọ̀dọ̀ Ọlọ́run!

TỌ́KÌ

IYE ÈÈYÀN

75,627,384

IYE AKÉDE

2,312

ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ BÍBÉLÌ

1,632

ÌPÍNDỌ́GBA

Akéde 1 máa wàásù fún èèyàn 32,711

Láti ọdún 2004 iye tí àwọn aṣáájú-ọ̀nà déédéé tó wà ní orílẹ̀-èdè Tọ́kì fi pọ̀ sí i jẹ́ 165%

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́