ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w14 7/15 ojú ìwé 1-2
  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2014
  • Ìsọ̀rí
  • Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2014
w14 7/15 ojú ìwé 1-2

Àwọn Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí

July 15, 2014

© 2014 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania

Ẹ̀DÀ TÓ WÀ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

SEPTEMBER 1-7, 2014

“Jèhófà Mọ Àwọn Tí Í Ṣe Tirẹ̀”

OJÚ ÌWÉ 7 • ORIN: 63, 66

SEPTEMBER 8-14, 2014

Àwọn Èèyàn Jèhófà “Kọ Àìṣòdodo Sílẹ̀ Ní Àkọ̀tán”

OJÚ ÌWÉ 12 • ORIN: 64, 61

SEPTEMBER 15-21, 2014

“Ẹ̀yin Ni Ẹlẹ́rìí Mi”

OJÚ ÌWÉ 23 • ORIN: 31, 92

SEPTEMBER 22-28, 2014

“Ẹ Ó sì Jẹ́ Ẹlẹ́rìí Mi”

OJÚ ÌWÉ 28 • ORIN: 102, 103

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

▪ “Jèhófà Mọ Àwọn Tí Í Ṣe Tirẹ̀”

▪ Àwọn Èèyàn Jèhófà “Kọ Àìṣòdodo Sílẹ̀ Ní Àkọ̀tán”

Àpilẹ̀kọ méjèèjì yìí ṣe àrúnkúnná ohun tí Bíbélì sọ nínú 2 Tímótì 2:19, wọ́n sì jẹ́ ká rí bí ẹsẹ Ìwé Mímọ́ yìí ṣe tan mọ́ àwọn ohun tó ṣẹlẹ̀ nígbà ayé Mósè. Àwọn àpilẹ̀kọ yìí á jẹ́ kí àwa Kristẹni mọ bí a ṣe lè fi hàn pé a ‘jẹ́ ti Jèhófà’ àti pé à ń “kọ àìṣòdodo sílẹ̀ ní àkọ̀tán.”

▪ “Ẹ̀yin Ni Ẹlẹ́rìí Mi”

▪ “Ẹ Ó sì Jẹ́ Ẹlẹ́rìí Mi”

Nínú àpilẹ̀kọ méjèèjì yìí, a máa jíròrò bó ti ṣe pàtàkì tó pé kéèyàn máa jẹ́ orúkọ náà, Ẹlẹ́rìí Jèhófà. Wàá rí i bó ṣe jẹ́ ohun àmúyangàn pé à ń jẹ́rìí nípa Jèhófà àti Jésù, èyí tó ń mú ká máa fìtara ṣe iṣẹ́ ìwàásù ká sì máa fi ìwà mímọ́ wa yin Ọlọ́run àti Kristi lógo.

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ MÍÌ NÍNÚ ÌTẸ̀JÁDE YÌÍ

3 Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn Tinútinú—Ní Micronesia

17 Baba Kú àmọ́, Baba Kù

ÀWÒRÁN IWÁJÚ ÌWÉ: Àwọn arábìnrin méjì yìí ń lo ìwé Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an? láti wàásù fún àwọn obìnrin méjì kan tí wọ́n jẹ́ ẹ̀yà Ndebele, tí wọ́n wọ aṣọ ìbílẹ̀, tí wọ́n sì jókòó níwájú ìta. Bí ilé táwọn Ndebele ń kọ́ sí abúlé ṣe máa ń rí nìyí. Tá a bá sì dá àwọn èèyàn tó ń gbé ní orílẹ̀-èdè South Africa sí ọgọ́rùn-ún, àwọn Ndebele ló kó ìdá méjì

SOUTH AFRICA

IYE ÈÈYÀN

50,500,000

GÓŃGÓ AKÉDE

94,101

ÀWỌN AKÉDE TÓ Ń SỌ ÈDÈ NDEBELE

1,003

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́