ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb16 September ojú ìwé 6
  • September 26 sí October 2

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • September 26 sí October 2
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
mwb16 September ojú ìwé 6

September 26 Sí October 2

SÁÀMÙ 142-150

  • Orin 134 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Jèhófà Tóbi, Ó sì Yẹ fún Ìyìn Gidigidi”: (10 min.)

    • Sm 145:1-9—Títóbi Jèhófà kò ní ààlà (w04 1/15 ojú ìwé 10 ìpínrọ̀ 3 àti 4; ojú ìwé 11 ìpínrọ̀ 7 àti 8; ojú ìwé 14 ìpínrọ̀ 20 àti 21; ojú ìwé 15 ìpínrọ̀ 2)

    • Sm 145:10-13—Àwọn tó jẹ́ adúróṣinṣin sí Jèhófà máa ń yìn ín (w04 1/15 ojú ìwé 16 ìpínrọ̀ 3 sí 6)

    • Sm 145:14-16—Jèhófà máa ń ti àwọn tó jẹ́ adúróṣinṣin sí i lẹ́yìn, ó sì máa ń bójú tó wọn (w04 1/15 ojú ìwé 17 àti 18 ìpínrọ̀ 10 sí 14)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Sm 143:8—Báwo ni Sáàmù 143:8 ṣe lè mú ká máa fi ògo fún Jèhófà ní gbogbo ọjọ́ ayé wa? (w10 1/15 ojú ìwé 21 ìpínrọ̀ 1 àti 2)

    • Sm 150:6—Kí ni ẹsẹ tó gbẹ̀yìn nínú ìwé Sáàmù rọ̀ wá pé ká máa ṣe? (it-2 ojú ìwé 448)

    • Ẹ̀kọ́ wo ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ mi nípa Jèhófà?

    • Àwọn kókó wo látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí ni mo lè lò lóde ẹ̀rí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Sm 145:1-21

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) 1Pe 5:7—Máa Fi Òtítọ́ Kọ́ni.

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Sm 37:9-11—Máa Fi Òtítọ́ Kọ́ni.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (6 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) fg ẹ̀kọ́ 9 ìpínrọ̀ 3—Ran akẹ́kọ̀ọ́ lọ́wọ́ kó lè rí bó ṣe lè fi ohun tó kọ́ sílò.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 99

  • “Mú Kí Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Rẹ Sunwọ̀n Sí I—Máa Fún Àwọn Tó Bá Nífẹ̀ẹ́ sí Ọ̀rọ̀ Wa Níṣìírí Láti Wá sí Ìpàdé”: (15 min.) Ìjíròrò. Fún àwọn ará ní ẹ̀dà kọ̀ọ̀kan ìwé ìkésíni tá a fi ń pe àwọn èèyàn wá sí ìpàdé ìjọ, kẹ́ ẹ sì jíròrò ojú ìwé 2 ní ṣókí. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò bí akéde kan ṣe ń pe ẹnì kan tó máa ń fún ní ìwé ìròyìn déédéé wá sí ìpàdé. Ní ìparí ọ̀rọ̀ rẹ, ẹ jíròrò àpótí náà “Ìwé Tá A Máa Lò Lóṣù October: Ìwé Ìkésíni sí Àwọn Ìpàdé Ìjọ.”

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) kr orí 1 ìpínrọ̀ 11 sí 20, àtẹ ìsọfúnni tó wà lójú ìwé “10” àti “12”

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 145 àti Àdúrà

    Ìránnilétí: Jẹ́ kí àwọn ará kọ́kọ́ gbọ́ orin tuntun yìí lẹ́ẹ̀kan, lẹ́yìn náà, kí ẹ kọ ọ́.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́