ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 January ojú ìwé 7
  • January 30–February 5

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • January 30–February 5
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 January ojú ìwé 7

January 30–February 5

Aísáyà 43-46

  • Orin 33 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Jèhófà Ni Ọlọ́run Tó Ń Sọ Àsọtẹ́lẹ̀ Tí Kìí Yẹ̀”: (10 min.)

    • Ais 44:26-28​—Jèhófà sọ tẹ́lẹ̀ pé wọ́n máa tún Jerúsálẹ́mù àti tẹ́ńpìlì rẹ̀ kọ́, ó sì tún sọ pé Kírúsì lẹni tó máa ṣẹ́gun ìlú Bábílónì (ip-2 71-72 ¶22-23)

    • Ais 45:1, 2​—Jèhófà sọ kúlẹ̀kúlẹ̀ nípa bí wọ́n ṣe máa ṣẹ́gun ìlú Bábílónì (ip-2 77-78 ¶4-6)

    • Ais 45:3-6​—Jèhófà sọ ìdí tó fi jẹ́ pé Kírúsì ni òun lò láti ṣẹ́gun ìlú Bábílónì (ip-2 79-80 ¶8-10)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Ais 43:10-12​—Ọ̀nà wo làwọn ọmọ Ísírẹ́lì gbà jẹ́ orílẹ̀-èdè tó jẹ́ ẹlẹ́rìí fún Jèhófà? (w14 11/⁠⁠15 21-22 ¶14-16)

    • Ais 43:25​—Kí nìdí tí Jèhófà fi ń mú àwọn ìrélànàkọjá wa kúrò? (ip-2 60 ¶24)

    • Ẹ̀kọ́ wo ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ mi nípa Jèhófà?

    • Àwọn kókó wo látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí ni mo lè lò lóde ẹ̀rí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ais 46:​1-13

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) fg​—Jẹ́rìí lọ́nà àìjẹ́ bí àṣà fún ẹni tẹ́ ẹ jọ ń ṣiṣẹ́ tàbí ọmọléèwé rẹ.

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) fg​—Jẹ́ kí onílé mọ̀ pé o máa pa dà wá.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (6 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) jl ẹ̀kọ́ 4

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 143

  • Báwo La Ṣe Mọ̀ Pé Òótọ́ ni Ọ̀rọ̀ Inú Bíbélì?: (15 min.) Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò yìí Báwo La Ṣe Mọ̀ Pé Òótọ́ ni Ọ̀rọ̀ Inú Bíbélì? Lẹ́yìn náà, béèrè àwọn ìbéèrè yìí: Báwo lá ṣe lè lo fídíò yìí nígbà tá a bá ń jẹ́rìí lọ́nà àìjẹ́-bí-àṣà, tá a bá ń wàásù níbi térò pọ̀ sí àti ilé-dé-ilé? Àwọn ìrírí tó dáa wo lo ní nígbà tó o lo fídíò yìí?

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) kr orí 7 ¶19-23, àpótí “JW.ORG,” àtẹ “Àwọn Ọ̀nà Kan Tí a Ti Gbà Mú Ìhìn Rere Dé Ọ̀dọ̀ Ọ̀pọ̀ Rẹpẹtẹ Èèyàn,” àti àpótí àtúnyẹ̀wò “Ṣé O Gbà Lóòótọ́ Pé Ìjọba Ọlọ́run Ti Ń Ṣàkóso?”

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 103 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́