ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 October ojú ìwé 5
  • October 16-22

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • October 16-22
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 October ojú ìwé 5

October 16-22

HÓSÉÀ 1-7

  • Orin 18 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Ṣé Inú Rẹ Máa Ń Dùn sí Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Bíi Ti Jèhófà?”: (10 min.)

    • [Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Hóséà.]

    • Ho 6:​4, 5​—Inú Jèhófà kò dùn sí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì torí pé wọn ò ní ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ (w10 8/15 25 ¶18)

    • Ho 6:6​—Inú Jèhófà máa ń dùn sí wa tá a bá ní ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ (w07 9/15 16 ¶8; w07 6/15 27 ¶7)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Ho 1:7​—Ìgbà wo ni Jèhófà fi àánú hàn sí ilé Júdà tó sì gbà wọ́n là? (w07 9/15 14 ¶7)

    • Ho 2:18​—Báwo ni ẹsẹ Bíbélì yìí ṣe ṣẹ nígbà àtijọ́, báwo ló sì ṣe máa ṣẹ lọ́jọ́ iwájú? (w05 11/15 20 ¶16; g05-E 9/8 12 ¶2)

    • Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ho 7:​1-16

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) 1Jo 5:3​—Máa Fi Òtítọ́ Kọ́ni​—Pe ẹni náà wá sí àwọn ìpàdé wa.

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Di 30:​11-14; Ais 48:​17, 18​—Máa Fi Òtítọ́ Kọ́ni​—Sọ fún ẹni náà nípa ìkànnì jw.org. (Wo mwb16.08 8 ¶2.)

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (6 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) lv 12-13 ¶16-18 ​—Fi béèyàn ṣe lè dé ọkàn akẹ́kọ̀ọ́ hàn.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 124

  • Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ: (15 min.) Alàgbà ni kó sọ àsọyé yìí. Mú ọ̀rọ̀ oníṣẹ̀ẹ́jú-márùn-ún tá a gbé ka Ìwé Mímọ́ tó o máa fi nasẹ̀ ọ̀rọ̀ rẹ jáde láti inú Ilé Ìṣọ́ November 15, 2015, ojú ìwé 14. Lẹ́yìn náà jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Bá A Ṣe Lè Fi Owó Ṣètìlẹ́yìn Látorí Íńtánẹ́ẹ̀tì. Tẹ́ ẹ bá ti wo fídíò náà tán, fi abala “Bó O Ṣe Lè Fi Ọrẹ Ti Iṣẹ́ Tá À Ń Ṣe Kárí Ayé Lẹ́yìn” han àwọn ará lórí ìkànnì jw.org/⁠yo. Kí o sì ṣàlàyé oríṣiríṣi àbá tó wà níbẹ̀ nípa ọ̀nà tí èèyàn lè gbà ṣètìlẹ́yìn lórí ìkànnì lórílẹ̀-èdè yín.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) kr orí 20 ¶1-6, àwọn àpótí “Ètò Ìrànwọ́ Àkọ́kọ́ Tó Kárí Ayé Lóde Òní,” “Bí A Ṣe Lè Múra Sílẹ̀ De Àjálù,” and “Nígbà Tí Àjálù Bá Ṣẹlẹ̀!”

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 50 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́