ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb19 July ojú ìwé 3
  • July 8-14

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • July 8-14
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2019
mwb19 July ojú ìwé 3

July 8-14

1 TẸSALÓNÍKÀ 1-5

  • Orin 90 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Ẹ Máa Fún Ara Yín Níṣìírí, Kí Ẹ sì Máa Gbé Ara Yín Ró”: (10 min.)

    • [Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Tẹsalóníkà Kìíní.]

    • 1Tẹ 5:11-13​—Ẹ máa ka àwọn tó ń ṣe àbójútó yín sí “lọ́nà àrà ọ̀tọ̀” (w11 6/15 26 ¶12; 28 ¶19)

    • 1Tẹ 5:14​—Ẹ sọ̀rọ̀ ìtùnú fún àwọn tó sorí kọ́, ẹ ran àwọn aláìlera lọ́wọ́ (w17.10 10 ¶13; w15 2/15 9 ¶16)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • 1Tẹ 4:3-6​—Ọ̀nà wo ni ẹni tó ṣe ìṣekúṣe gbà “yan arákùnrin rẹ̀ jẹ”? it-1 863-864)

    • 1Tẹ 4:15-17​—Àwọn wo la máa ‘gbà lọ nínú àwọsánmà láti pàdé Olúwa nínú afẹ́fẹ́,’ báwo ló sì ṣe máa ṣẹlẹ̀? (w15 7/15 18-19 ¶14-15)

    • Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) 1Tẹ 3:1-13 (th ẹ̀kọ́ 5)

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́—Fídíò: (4 min.) Ẹ wo fídíò náà, kẹ́ ẹ sì jíròrò rẹ̀.

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. (th ẹ̀kọ́ 1)

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. Onílé sọ ohun táwọn èèyàn sábà máa ń sọ ní ìpínlẹ̀ yín tí wọn kò bá fẹ́ gbọ́ ìwàásù. Fèsì ní ṣókí, kó o sì máa bá ọ̀rọ̀ rẹ lọ. (th ẹ̀kọ́ 3)

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. Onílé sọ ohun táwọn èèyàn sábà máa ń sọ ní ìpínlẹ̀ yín tí wọn kò bá fẹ́ gbọ́ ìwàásù. Fèsì ní ṣókí, kó o sì máa bá ọ̀rọ̀ rẹ lọ. (th ẹ̀kọ́ 4)

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 81

  • Àwọn Aṣáájú-Ọ̀nà Máa Ń Fún Àwọn Míì Níṣìírí: (9 min.) Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà Àwọn Aṣáájú-Ọ̀nà Ń Ṣe Bẹbẹ. Lẹ́yìn náà kẹ́ ẹ dáhùn àwọn ìbéèrè yìí: Báwo ni àwọn aṣáájú-ọ̀nà ṣe lè fún àwọn ará ìjọ níṣìírí? Ìṣírí wo lo ti rí gbà látọ̀dọ̀ àwọn aṣáájú-ọ̀nà tó wà nínú ìjọ rẹ?

  • Àwọn Àpẹẹrẹ Rere Tó Lè Fún Wa Níṣìírí: (6 min.) Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà A Gbọ́dọ̀ ‘Fi Ìfaradà Sáré’​—Máa Tẹ̀ Lé Àwọn Àpẹẹrẹ Rere. Lẹ́yìn náà kẹ́ ẹ dáhùn àwọn ìbéèrè yìí: Ìṣòro wo ni arábìnrin yẹn ní? Kí ló ṣe tó fi rí ìṣírí gbà?

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) bh orí 8 ¶1-7

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 100 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́