ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 August ojú ìwé 8
  • August 31–September 6

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • August 31–September 6
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 August ojú ìwé 8

August 31–September 6

Ẹ́KÍSÓDÙ 21-22

  • Orin 141 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Jẹ́ Kí Ẹ̀mí Jọ Ẹ́ Lójú Bíi Ti Jèhófà”: (10 min.)

    • Ẹk 21:20​—Jèhófà dẹ́bi fún ìpànìyàn (it-1 271)

    • Ẹk 21:​22, 23​—Ẹ̀mí ọmọ tó wà nínú oyún ṣeyebíye lójú Jèhófà (lv 80 ¶16)

    • Ẹk 21:​28, 29​—Jèhófà ò fẹ́ ká fọ̀rọ̀ ààbò ṣeré rárá (w10 4/15 29 ¶4)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (10 min.)

    • Ẹk 21:​5, 6​—Báwo ni ẹsẹ Bíbélì yìí ṣe jẹ́ ká rí i pé ìyàsímímọ́ máa ń ṣe wá láǹfààní? (w10 1/15 4 ¶4-5)

    • Ẹk 21:14​—Kí ló ṣeé ṣe kí ẹsẹ Bíbélì yìí túmọ̀ sí? (it-1 1143)

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ẹk 21:​1-21 (th ẹ̀kọ́ 5)

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. Pe ẹni náà wá sí àwọn ìpàdé wa. (th ẹ̀kọ́ 2)

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ tó wà lójú ìwé 1. Ṣe bíi pé ẹ wo fídíò Kí Ló Máa Ń Ṣẹlẹ̀ Nínú Gbọ̀ngàn Ìjọba? (àmọ́ ẹ má ṣe wò ó) (th ẹ̀kọ́ 20)

  • Àsọyé: (5 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) w09 4/1 31​—Àkòrí: Jèhófà Ni Bàbá Àwọn Ọmọ Aláìníbaba. (th ẹ̀kọ́ 19)

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 60

  • Fi Hàn Pé Ẹ̀mí Èèyàn Jọ Ẹ́ Lójú: (10 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà. Lẹ́yìn ìyẹn, béèrè àwọn ìbéèrè yìí: Àwọn ìṣòro wo ló ṣeé ṣe kó yọjú tí obìnrin kan bá lóyún? Báwo ni Ẹ́kísódù 21:​22, 23 ṣe jẹ́ ká mọ̀ pé kò dáa kéèyàn ṣẹ́yún? Kí nìdí tá a fi nílò ìgbàgbọ́ àti ìgboyà ká lè ṣe ìpinnu tó máa múnú Jèhófà dùn? Báwo ni ìrètí àjíǹde ṣe ń tù wá nínú?

  • Bí Ìyàsímímọ́ Ṣe Ń Ṣe Wá Láǹfààní: (5 min.) Àsọyé tó dá lórí Ilé Ìṣọ́ January 15, 2010, ojú ìwé 4, ìpínrọ̀ 4-7. Gba àwọn tó ń kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì níyànjú pé kí wọ́n ya ara wọn sí mímọ́, kí wọ́n sì ṣèrìbọmi.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) jy orí 130

  • Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

  • Orin 15 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́