ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 642
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ẹ́sírà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ẹ́sírà
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Ẹ́sírà
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2006
  • Gbígbẹ́kẹ̀lé Ìrànlọ́wọ́ Ọlọ́run
    Ìwé Ìtàn Bíbélì
  • Jẹ́ Kó Túbọ̀ Dá Ẹ Lójú Pé Jèhófà Máa Ràn Ẹ́ Lọ́wọ́ Nígbà Ìṣòro
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2023
  • Jèhófà Máa Ń Mú Àwọn Ìlérí Rẹ̀ Ṣẹ
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ẹ́sírà

Ẹ́SÍRÀ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Ọba Kírúsì pàṣẹ pé kí wọ́n tún tẹ́ńpìlì kọ́ (1-4)

    • Ètò tí wọ́n ṣe kí àwọn tó wà nígbèkùn ní Bábílónì lè pa dà (5-11)

  • 2

    • Orúkọ àwọn tó pa dà láti ìgbèkùn (1-67)

      • Àwọn ìránṣẹ́ tẹ́ńpìlì (43-54)

      • Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Sólómọ́nì (55-57)

    • Àwọn ọrẹ àtinúwá fún tẹ́ńpìlì (68-70)

  • 3

    • Wọ́n tún pẹpẹ kọ́, wọ́n sì rú àwọn ẹbọ (1-6)

    • Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í tún tẹ́ńpìlì kọ́ (7-9)

    • Wọ́n fi ìpìlẹ̀ tẹ́ńpìlì lélẹ̀ (10-13)

  • 4

    • Wọ́n gbógun ti iṣẹ́ títún tẹ́ńpìlì kọ́ (1-6)

    • Àwọn ọ̀tá fi ìwé ẹ̀sùn ránṣẹ́ sí Ọba Atasásítà (7-16)

    • Ìdáhùn Atasásítà (17-22)

    • Iṣẹ́ kíkọ́ tẹ́ńpìlì dáwọ́ dúró (23-24)

  • 5

    • Àwọn Júù pa dà sẹ́nu kíkọ́ tẹ́ńpìlì (1-5)

    • Lẹ́tà tí Táténáì kọ sí Ọba Dáríúsì (6-17)

  • 6

    • Àyẹ̀wò tí Dáríúsì ṣe àti àṣẹ tó pa (1-12)

    • Wọ́n parí tẹ́ńpìlì, wọ́n sì ṣe ayẹyẹ ìṣílé (13-18)

    • Wọ́n ṣe Ìrékọjá (19-22)

  • 7

    • Ẹ́sírà wá sí Jerúsálẹ́mù (1-10)

    • Lẹ́tà tí Atasásítà kọ sí Ẹ́sírà (11-26)

    • Ẹ́sírà yin Jèhófà (27-28)

  • 8

    • Orúkọ àwọn tó tẹ̀ lé Ẹ́sírà pa dà (1-14)

    • Wọ́n múra ìrìn àjò náà (15-30)

    • Wọ́n kúrò ní Bábílónì, wọ́n dé sí Jerúsálẹ́mù (31-36)

  • 9

    • Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì àti àwọn ọmọ ilẹ̀ míì ń fẹ́ ara wọn (1-4)

    • Àdúrà ìjẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí Ẹ́sírà gbà (5-15)

  • 10

    • Wọ́n dá májẹ̀mú láti lé àwọn aya àjèjì lọ (1-14)

    • Wọ́n lé àwọn aya àjèjì lọ (15-44)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́