ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sjj orin 161
  • Inú Mi Ń Dùn Láti Ṣe Ìfẹ́ Rẹ

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Inú Mi Ń Dùn Láti Ṣe Ìfẹ́ Rẹ
  • “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Orísun Ayọ̀ Wa
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Ohun Tó Ń Fún Wa Láyọ̀
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Ìbéèrè Láti Ọwọ́ Àwọn Òǹkàwé
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
  • Ìdí Ayọ̀ Wa Pọ̀
    Kọrin sí Jèhófà
Àwọn Míì
“Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
sjj orin 161

ORIN 161

Inú Mi Ń Dùn Láti Ṣe Ìfẹ́ Rẹ

Bíi Ti Orí Ìwé

(Sáàmù 40:8)

  1. 1. Nígbà tí Jésù ṣèrìbọmi

    Ní inú Odò Jọ́dánì,

    Gbogbo ohun tó wà lọ́kàn rẹ̀

    Ni láti ṣe ìfẹ́ Jáà.

    Ó borí ìdẹwò Sátánì.

    Ó fi ìtara wàásù.

    Ó ń láyọ̀ torí pó ń ṣèfẹ́ Jáà.

    Èmi náà ti pinnu pé:

    (ÈGBÈ)

    Màá fayọ̀ ṣèfẹ́ rẹ Baba.

    Ẹnu mi yóò máa ròyìn rẹ.

    Mò ń láyọ̀ gan-an látọkàn wá,

    Bí mo ṣe ń ṣe ìfẹ́ rẹ.

    Màá fayé mi sìn ọ́ Baba.

    Ìwọ l’Orísun ayọ̀ mi.

    Ìfẹ́ tòótọ́ lo ní sí mi.

    Títí láé nìyìn rẹ máa

    Wà lẹ́nu mi!

  2. 2. Bí mo ṣe wá mọ̀ ọ́ Jèhófà,

    Ayé mi ti wá dára sí i.

    Mo fi gbogbo ayé mi fún ọ.

    Tìrẹ ni màá máa ṣe láé.

    Mò ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú àwọn ará,

    Tí a jọ ń ṣe ìfẹ́ rẹ.

    Gbogbo iṣẹ́ àgbàyanu rẹ,

    Ni màá kéde fáráyé.

    (ÈGBÈ)

    Màá fayọ̀ ṣèfẹ́ rẹ Baba.

    Ẹnu mi yóò máa ròyìn rẹ.

    Mò ń láyọ̀ gan-an látọkàn wá,

    Bí mo ṣe ń ṣe ìfẹ́ rẹ.

    Màá fayé mi sìn ọ́ Baba.

    Ìwọ l’Orísun ayọ̀ mi.

    Ìfẹ́ tòótọ́ lo ní sí mi.

    Títí láé nìyìn rẹ máa

    Wà lẹ́nu mi!

    Màá fayọ̀ ṣèfẹ́ rẹ!

(Tún wo Sm. 40:3, 10.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́