ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb21 March ojú ìwé 6
  • Bí Ìgbàgbọ́ Ṣe Lè Jẹ́ Ká Nígboyà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Bí Ìgbàgbọ́ Ṣe Lè Jẹ́ Ká Nígboyà
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ráhábù Fi Àwọn Amí Pa Mọ́
    Ìwé Ìtàn Bíbélì
  • Àwọn Amí Méjìlá
    Àwọn Ẹ̀kọ́ Tó O Lè Kọ́ Látinú Bíbélì
  • “Ẹ Lé Gbogbo Àwọn Tó Ń Gbé Ilẹ̀ Náà Kúrò”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Àwọn Amí Méjìlá
    Ìwé Ìtàn Bíbélì
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
mwb21 March ojú ìwé 6
Jóṣúà àti Kélẹ́bù ń fi òṣùṣù èso àjàrà tó tóbi han àwọn amí tó kù.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Bí Ìgbàgbọ́ Ṣe Lè Jẹ́ Ká Nígboyà

Àwọn amí tó mú ìròyìn burúkú wá ò nígbàgbọ́ (Nọ 13:​31-33; 14:11)

Torí pé àwọn amí mẹ́wàá yẹn ò nígbàgbọ́, wọ́n kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn tó kù (Nọ 14:​1-4)

Àwọn amí tó jẹ́ onígboyà fi hàn pé àwọn ní ìgbàgbọ́ tó lágbára (Nọ 14:​6-9; w06 10/1 17 ¶5-6)

Ṣáájú ìgbà yẹn, àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ti fojú ara wọn rí bí Jèhófà ṣe gbà wọ́n là, tó sì jà fún wọn. Ó yẹ kí àwọn nǹkan tí wọ́n rí yẹn mú kí ìgbàgbọ́ wọn lágbára, kí wọ́n sì gbà pé Jèhófà máa ràn wọ́n lọ́wọ́ láti ṣẹ́gun àwọn ọmọ Kénáánì.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́