ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • ijwbq àpilẹ̀kọ 7
  • Ṣé Ẹni Gidi Ni Ọlọ́run?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ṣé Ẹni Gidi Ni Ọlọ́run?
  • Ohun Tí Bíbélì Sọ
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun tí Bíbélì sọ
  • Àwọn Ìràwọ̀ Ń Fi Agbára Ọlọ́run Hàn
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • Ta Ni Jèhófà?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
  • Kí Ni Ẹ̀mí Mímọ́ Ọlọ́run?
    Jí!—1999
  • Ṣé Lílò Tí Ọlọ́run Ń Lo Agbára Rẹ̀ Láti Pa Àwọn Ẹni Ibi Run Tọ̀nà?
    Jí!—2001
Àwọn Míì
Ohun Tí Bíbélì Sọ
ijwbq àpilẹ̀kọ 7
Ọkùnrin kan ń wo àwọn ìràwọ̀

Ṣé Ẹni Gidi Ni Ọlọ́run?

Ohun tí Bíbélì sọ

Agbára tí Ọlọ́run ní kò láfiwé. Nígbà tí Bíbélì ń sọ̀rọ̀ nípa bó ṣe dá àìmọye ìràwọ̀, ó sọ pé: “Ẹ gbé ojú yín sókè réré, kí ẹ sì wò. Ta ni ó dá nǹkan wọ̀nyí? Ẹni tí ń mú ẹgbẹ́ ọmọ ogun wọn jáde wá ni, àní ní iye-iye, àwọn tí ó jẹ́ pé àní orúkọ ni [Ọlọ́run] fi ń pe gbogbo wọn. Nítorí ọ̀pọ̀ yanturu okun rẹ̀ alágbára gíga, àti ní ti pé òun ní okun inú nínú agbára, kò sí ìkankan nínú wọn tí ó dàwáàrí.”—Aísáyà 40:25, 26.

Àmọ́, ẹni gidi ni Ọlọ́run, kì í ṣe agbára àìrí kan. Bíbélì sọ pé Ọlọ́run máa ń mọ nǹkan lára, ó láwọn nǹkan tó nífẹ̀ẹ́ sí àtàwọn ohun tó kórìíra. (Sáàmù 11:5; Jòhánù 3:16) Ó tún jẹ́ ká mọ̀ pé ohun tí a bá ṣe lè mú kí inú Ọlọ́run dùn tàbí kí inú rẹ̀ bà jẹ́.—Sáàmù 78:40, 41.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́