ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • ijwbq àpilẹ̀kọ 10
  • Ṣé Jésù Ni Orúkọ Ọlọ́run?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ṣé Jésù Ni Orúkọ Ọlọ́run?
  • Ohun Tí Bíbélì Sọ
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun tí Bíbélì sọ
  • Nípa Ọlọ́run Tòótọ́
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • O Ha Níláti Gbàdúrà sí Jesu Bí?
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1994
  • Ta Ni Jésù Kristi?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • Orúkọ Ọlọ́run
    Jí!—2017
Àwọn Míì
Ohun Tí Bíbélì Sọ
ijwbq àpilẹ̀kọ 10
Jésù ń gbàdúrà

Ṣé Jésù Ni Orúkọ Ọlọ́run?

Ohun tí Bíbélì sọ

Jésù pe ara rẹ̀ ní “Ọmọ Ọlọ́run.” (Jòhánù 10:36; 11:4) Jésù kò pe ara rẹ̀ ní Ọlọ́run Olódùmarè.

Yàtọ̀ sí yẹn, Jésù gbàdúrà sí Ọlọ́run. Nígbà tó sì ń kọ́ àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ bí wọ́n ṣe máa gbàdúrà, ó sọ pé: “Baba wa tí ń bẹ ní ọ̀run, kí orúkọ rẹ di sísọ di mímọ́.”—Mátíù 6:9.

Jésù ṣí orúkọ Ọlọ́run payá nígbà tó fa ọ̀rọ̀ yọ látinú ẹsẹ Ìwé Mímọ́ kan, tí wọ́n kọ láyé àtijọ́, ó sọ pé: “Gbọ́, Ìwọ Ísírẹ́lì, Jèhófà Ọlọ́run wa jẹ́ Jèhófà kan ṣoṣo.”—Máàkù 12:29; Diutarónómì 6:4.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́