ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sjj orin 68
  • Máa Fún Irúgbìn Ìjọba Náà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Máa Fún Irúgbìn Ìjọba Náà
  • “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Fífúnrúgbìn Èso Ìjọba Ọlọ́run
    Kọrin sí Jèhófà
  • Irú Ọmọ Ejò náà—Báwo ni A Ṣe Tú u Fó?
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1996
  • ‘Ọlọ́run Ló Ń Mú Kí Ó Dàgbà’!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • Lájorí Ẹṣin Ọ̀rọ̀ Bíbélì
    Ìṣípayá—Ìparí Rẹ̀ Ológo Kù sí Dẹ̀dẹ̀!
Àwọn Míì
“Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
sjj orin 68

ORIN 68

Máa Fún Irúgbìn Ìjọba Náà

Bíi Ti Orí Ìwé

(Mátíù 13:4-8)

  1. 1. Ọ̀gá wa ń pè ọ́ pé kóo máa bọ̀,

    Kó o wá ṣe nínú iṣẹ́ rẹ̀.

    Fọkàn balẹ̀, yóò tọ́ ẹ sọ́nà,

    Ó sì tún máa dá ẹ lẹ́kọ̀ọ́.

    Inú ọkàn àwọn onírẹ̀lẹ̀

    Nirúgbìn òótọ́ ti máa ń hù.

    Torí náà, rí i pé o sa gbogbo ‘pá rẹ

    Kó o lè ṣiṣẹ́ tá a yàn fún ọ yìí.

  2. 2. Tíṣẹ́ rẹ bá máa sèso rere,

    Nígbà míì, ọwọ́ rẹ ló wà.

    Fìfẹ́ kọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ rẹ

    Kí wọ́n lè nífẹ̀ẹ́ òtítọ́.

    Kọ́ wọn bí wọ́n ṣe máa kojú ‘ṣòro

    Àt’àdánwò tó bá yọjú.

    Inú rẹ máa dùn tó o bá rí bí wọ́n ṣe

    Ń fi òótọ́ tí wọ́n ń kọ́ yìí sílò.

(Tún wo Mát. 13:​19-23; 22:37.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́