ÀPÓTÍ Ẹ̀KỌ́ 5A
“Ọmọ Èèyàn, Ṣé Ìwọ Náà Rí I?”
Bíi Ti Orí Ìwé
Ohun mẹ́rin tó ń kóni nírìíra tí Ìsíkíẹ́lì rí nínú àgbàlá àti tẹ́ńpìlì. (Ìsík. 8:5-16)
1. ÈRE OWÚ
2. ÀÁDỌ́RIN ÀGBÀÀGBÀ TÍ WỌ́N Ń SUN TÙRÀRÍ SÍ ÀWỌN ÒRÌṢÀ
3. “ÀWỌN OBÌNRIN . . . TÍ WỌ́N Ń SUNKÚN TORÍ ỌLỌ́RUN TÍ WỌ́N Ń PÈ NÍ TÁMÚSÌ”
4. ỌKÙNRIN MẸ́Ẹ̀Ẹ́DỌ́GBỌ̀N TÍ “WỌ́N Ń FORÍ BALẸ̀ FÚN OÒRÙN”