ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Nọ́ńbà 22:16, 17
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 16 Wọ́n wá sọ́dọ̀ Báláámù, wọ́n sì sọ fún un pé: “Ohun tí Bálákì ọmọ Sípórì sọ nìyí, ‘Jọ̀ọ́, má ṣe jẹ́ kí ohunkóhun dí ọ lọ́wọ́ láti wá sọ́dọ̀ mi, 17 torí màá dá ọ lọ́lá gan-an, ohunkóhun tí o bá sì ní kí n ṣe ni màá ṣe. Torí náà, jọ̀ọ́ máa bọ̀, wá bá mi gégùn-ún fún àwọn èèyàn yìí.’”

  • Nọ́ńbà 24:10, 11
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 10 Inú wá bí Bálákì sí Báláámù gan-an. Bálákì wá fi ìbínú pàtẹ́wọ́, ó sì sọ fún Báláámù pé: “Torí kí o lè gégùn-ún fún àwọn ọ̀tá mi ni mo ṣe pè ọ́ + wá, àmọ́ ṣe lo kàn ń súre fún wọn lẹ́ẹ̀mẹta yìí. 11 Ó yá, tètè pa dà sílé. Mo fẹ́ dá ọ lọ́lá gan-an+ tẹ́lẹ̀ ni, àmọ́ wò ó! Jèhófà ò jẹ́ kí n dá ọ lọ́lá.”

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́