-
Nehemáyà 9:7, 8Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
7 Ìwọ ni Jèhófà Ọlọ́run tòótọ́, tó yan Ábúrámù,+ tó mú un jáde kúrò ní Úrì,+ ìlú àwọn ará Kálídíà, tó sì sọ orúkọ rẹ̀ ní Ábúráhámù.+ 8 O rí i pé ó jẹ́ olóòótọ́ níwájú rẹ,+ torí náà, o bá a dá májẹ̀mú láti fún un ní ilẹ̀ àwọn ọmọ Kénáánì, àwọn ọmọ Hétì, àwọn Ámórì, àwọn Pérísì, àwọn ará Jébúsì àti àwọn Gẹ́gáṣì, pé kó fún àwọn ọmọ* rẹ̀;+ o sì mú ìlérí rẹ ṣẹ nítorí pé olódodo ni ọ́.
-