Jẹ́nẹ́sísì 2:7 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 7 Jèhófà Ọlọ́run fi erùpẹ̀+ ilẹ̀ mọ ọkùnrin, ó mí èémí ìyè+ sí ihò imú rẹ̀, ọkùnrin náà sì di alààyè.*+ Àìsáyà 45:9 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 9 Ó mà ṣe fún ẹni tó ń bá Aṣẹ̀dá rẹ̀* fa nǹkan* o,Torí ó dà bí àfọ́kù ìkòkò lásánLáàárín àwọn àfọ́kù ìkòkò míì tó wà nílẹ̀! Ṣé ó yẹ kí amọ̀ sọ fún Amọ̀kòkò* pé: “Kí lò ń mọ?”+ Àbí ó yẹ kí iṣẹ́ rẹ sọ pé: “Kò ní ọwọ́”?* Àìsáyà 64:8 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 8 Àmọ́ ní báyìí, Jèhófà, ìwọ ni Bàbá wa.+ Àwa ni amọ̀, ìwọ sì ni Ẹni tó mọ wá;*+Iṣẹ́ ọwọ́ rẹ ni gbogbo wa. Róòmù 9:21 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 21 Kí wá ni? Ṣé amọ̀kòkò ò láṣẹ lórí amọ̀+ láti fi lára ìṣùpọ̀ rẹ̀ mọ ohun èlò* kan fún ìlò tó lọ́lá, kí ó sì fi lára rẹ̀ mọ ohun èlò míì fún ìlò tí kò lọ́lá?
7 Jèhófà Ọlọ́run fi erùpẹ̀+ ilẹ̀ mọ ọkùnrin, ó mí èémí ìyè+ sí ihò imú rẹ̀, ọkùnrin náà sì di alààyè.*+
9 Ó mà ṣe fún ẹni tó ń bá Aṣẹ̀dá rẹ̀* fa nǹkan* o,Torí ó dà bí àfọ́kù ìkòkò lásánLáàárín àwọn àfọ́kù ìkòkò míì tó wà nílẹ̀! Ṣé ó yẹ kí amọ̀ sọ fún Amọ̀kòkò* pé: “Kí lò ń mọ?”+ Àbí ó yẹ kí iṣẹ́ rẹ sọ pé: “Kò ní ọwọ́”?*
8 Àmọ́ ní báyìí, Jèhófà, ìwọ ni Bàbá wa.+ Àwa ni amọ̀, ìwọ sì ni Ẹni tó mọ wá;*+Iṣẹ́ ọwọ́ rẹ ni gbogbo wa.
21 Kí wá ni? Ṣé amọ̀kòkò ò láṣẹ lórí amọ̀+ láti fi lára ìṣùpọ̀ rẹ̀ mọ ohun èlò* kan fún ìlò tó lọ́lá, kí ó sì fi lára rẹ̀ mọ ohun èlò míì fún ìlò tí kò lọ́lá?