ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Jóòbù 34:19
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 19 Ẹnì kan wà tí kì í ṣe ojúsàájú àwọn olórí,

      Tí kì í sì í ka ọlọ́rọ̀ sí ju aláìní lọ,*+

      Torí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀ ni gbogbo wọn.+

  • Òwe 14:31
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 31 Ẹni tó ń lu aláìní ní jìbìtì ń gan Ẹni tó dá a,+

      Àmọ́ ẹni tó ń ṣàánú tálákà ń yìn Ín lógo.+

  • Òwe 22:2
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  2 Ohun tí ọlọ́rọ̀ àti aláìní fi jọra* ni pé:

      Jèhófà ló dá àwọn méjèèjì.+

  • Málákì 2:10
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 10 “Ṣebí bàbá kan ni gbogbo wa ní?+ Àbí Ọlọ́run kan náà kọ́ ló dá wa? Kí ló wá dé tí a fi ń dalẹ̀ ara wa,+ tí a sì ń pẹ̀gàn májẹ̀mú àwọn baba ńlá wa?

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́