Ẹ́kísódù 6:3 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 3 Mo ti máa ń fara han Ábúráhámù, Ísákì àti Jékọ́bù pé èmi ni Ọlọ́run Olódùmarè,+ àmọ́ ní ti orúkọ mi Jèhófà,+ mi ò jẹ́ kí wọ́n fi mọ̀ mí.+ Sáàmù 68:4 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 4 Ẹ kọrin sí Ọlọ́run; ẹ fi orin yin* orúkọ rẹ̀.+ Ẹ kọrin sí Ẹni tó ń la àwọn aṣálẹ̀ tó tẹ́jú* kọjá. Jáà* ni orúkọ rẹ̀!+ Ẹ máa yọ̀ níwájú rẹ̀! Àìsáyà 42:8 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 8 Èmi ni Jèhófà. Orúkọ mi nìyẹn;Èmi kì í fi ògo mi fún ẹlòmíì,*Èmi kì í sì í fi ìyìn mi fún àwọn ère gbígbẹ́.+ Àìsáyà 54:5 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 5 “Torí pé Aṣẹ̀dá rẹ Atóbilọ́lá+ dà bí ọkọ* rẹ,+Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun ni orúkọ rẹ̀,Ẹni Mímọ́ Ísírẹ́lì sì ni Olùtúnrà rẹ.+ Ọlọ́run gbogbo ayé la ó máa pè é.+
3 Mo ti máa ń fara han Ábúráhámù, Ísákì àti Jékọ́bù pé èmi ni Ọlọ́run Olódùmarè,+ àmọ́ ní ti orúkọ mi Jèhófà,+ mi ò jẹ́ kí wọ́n fi mọ̀ mí.+
4 Ẹ kọrin sí Ọlọ́run; ẹ fi orin yin* orúkọ rẹ̀.+ Ẹ kọrin sí Ẹni tó ń la àwọn aṣálẹ̀ tó tẹ́jú* kọjá. Jáà* ni orúkọ rẹ̀!+ Ẹ máa yọ̀ níwájú rẹ̀!
8 Èmi ni Jèhófà. Orúkọ mi nìyẹn;Èmi kì í fi ògo mi fún ẹlòmíì,*Èmi kì í sì í fi ìyìn mi fún àwọn ère gbígbẹ́.+
5 “Torí pé Aṣẹ̀dá rẹ Atóbilọ́lá+ dà bí ọkọ* rẹ,+Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun ni orúkọ rẹ̀,Ẹni Mímọ́ Ísírẹ́lì sì ni Olùtúnrà rẹ.+ Ọlọ́run gbogbo ayé la ó máa pè é.+