Sáàmù 126:2 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 2 Ní àkókò yẹn, ẹ̀rín kún ẹnu wa,Ahọ́n wa sì ń kígbe ayọ̀.+ Ní àkókò yẹn, wọ́n ń sọ láàárín àwọn orílẹ̀-èdè pé: “Jèhófà ti ṣe àwọn ohun ńlá fún wọn.”+ Àìsáyà 49:13 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 13 Ẹ kígbe ayọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, sì máa yọ̀, ìwọ ayé.+ Kí inú àwọn òkè dùn, kí wọ́n sì kígbe ayọ̀.+ Torí Jèhófà ti tu àwọn èèyàn rẹ̀ nínú,+Ó sì ń ṣàánú àwọn èèyàn rẹ̀ tí ìyà ń jẹ.+ Jeremáyà 51:48 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 48 Àwọn ọ̀run àti ayé àti gbogbo ohun tó wà nínú wọnMáa kígbe ayọ̀ lórí Bábílónì,+Nítorí pé àwọn apanirun máa wá bá a láti àríwá,”+ ni Jèhófà wí. Ìfihàn 18:20 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 20 “Máa yọ̀ nítorí rẹ̀, ìwọ ọ̀run+ àti ẹ̀yin ẹni mímọ́,+ ẹ̀yin àpọ́sítélì àti wòlíì, torí pé Ọlọ́run ti kéde ìdájọ́ sórí rẹ̀ nítorí yín!”+
2 Ní àkókò yẹn, ẹ̀rín kún ẹnu wa,Ahọ́n wa sì ń kígbe ayọ̀.+ Ní àkókò yẹn, wọ́n ń sọ láàárín àwọn orílẹ̀-èdè pé: “Jèhófà ti ṣe àwọn ohun ńlá fún wọn.”+
13 Ẹ kígbe ayọ̀, ẹ̀yin ọ̀run, sì máa yọ̀, ìwọ ayé.+ Kí inú àwọn òkè dùn, kí wọ́n sì kígbe ayọ̀.+ Torí Jèhófà ti tu àwọn èèyàn rẹ̀ nínú,+Ó sì ń ṣàánú àwọn èèyàn rẹ̀ tí ìyà ń jẹ.+
48 Àwọn ọ̀run àti ayé àti gbogbo ohun tó wà nínú wọnMáa kígbe ayọ̀ lórí Bábílónì,+Nítorí pé àwọn apanirun máa wá bá a láti àríwá,”+ ni Jèhófà wí.
20 “Máa yọ̀ nítorí rẹ̀, ìwọ ọ̀run+ àti ẹ̀yin ẹni mímọ́,+ ẹ̀yin àpọ́sítélì àti wòlíì, torí pé Ọlọ́run ti kéde ìdájọ́ sórí rẹ̀ nítorí yín!”+