-
Jeremáyà 15:20Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
20 “Màá sọ ọ́ di odi bàbà tó lágbára sí àwọn èèyàn yìí.+
-
-
Jeremáyà 33:1Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
33 Jèhófà bá Jeremáyà sọ̀rọ̀ lẹ́ẹ̀kejì, nígbà tó ṣì wà ní àhámọ́ ní Àgbàlá Ẹ̀ṣọ́,+ pé:
-
-
Jeremáyà 39:13, 14Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
13 Torí náà, Nebusarádánì olórí ẹ̀ṣọ́ àti Nebuṣásíbánì tó jẹ́ Rábúsárísì* àti Nẹgali-ṣárésà tó jẹ́ Rábúmágì* pẹ̀lú gbogbo èèyàn sàràkí-sàràkí ọba Bábílónì ránṣẹ́ 14 pé kí wọ́n mú Jeremáyà jáde kúrò ní Àgbàlá Ẹ̀ṣọ́,+ wọ́n sì fà á lé ọwọ́ Gẹdaláyà+ ọmọ Áhíkámù+ ọmọ Ṣáfánì,+ láti mú un wá sí ilé rẹ̀. Torí náà, ó ń gbé ní àárín àwọn èèyàn náà.
-