-
2 Kíróníkà 34:20, 21Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
20 Ọba wá pa àṣẹ yìí fún Hilikáyà, Áhíkámù+ ọmọ Ṣáfánì, Ábídónì ọmọ Míkà, Ṣáfánì akọ̀wé àti Ásáyà ìránṣẹ́ ọba pé: 21 “Ẹ lọ bá èmi àti àwọn tó ṣẹ́ kù ní Ísírẹ́lì àti ní Júdà wádìí lọ́dọ̀ Jèhófà nípa àwọn ọ̀rọ̀ inú ìwé tí a rí yìí; nítorí ìbínú Jèhófà tó máa tú jáde sórí wa pọ̀ gan-an torí àwọn baba ńlá wa kò pa ọ̀rọ̀ Jèhófà mọ́, wọn ò ṣe gbogbo ohun tó wà lákọsílẹ̀ nínú ìwé yìí.”+
-