58 Ohun tí Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun sọ nìyí:
“Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ògiri Bábílónì fẹ̀, a ó wó o palẹ̀,+
Bó tiẹ̀ jẹ́ pé àwọn ẹnubodè rẹ̀ ga, a ó sọ iná sí i.
Àwọn èèyàn ibẹ̀ á sì ṣe làálàá lásán;
Àwọn orílẹ̀-èdè á ṣiṣẹ́ títí á fi rẹ̀ wọ́n, torí iná náà kò ní ṣeé pa.”+