-
Diutarónómì 28:15Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
15 “Àmọ́ tí o ò bá pa gbogbo àṣẹ àti òfin Jèhófà Ọlọ́run rẹ mọ́, èyí tí mò ń pa láṣẹ fún ọ lónìí, láti fi hàn pé ò ń fetí sí ohùn rẹ̀, gbogbo ègún yìí máa wá sórí rẹ, ó sì máa bá ọ:+
-
-
Àìsáyà 3:1Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
3 Wò ó! Olúwa tòótọ́, Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun,
Ó ń mú gbogbo ìtìlẹ́yìn àtàwọn ohun tí wọ́n nílò ní Jerúsálẹ́mù àti Júdà kúrò,
Gbogbo ìtìlẹ́yìn oúnjẹ àti omi,+
-
Ìsíkíẹ́lì 4:11Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
-
-
11 “Ṣe ni wàá máa wọn omi tí o fẹ́ mu, ìdá mẹ́fà òṣùwọ̀n hínì* lo máa wọ̀n. Tí àkókò bá tó ni wàá mu ún.
-
-
-