1 Àwọn Ọba 14:9 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 9 Ohun tí o ṣe burú ju ti gbogbo àwọn tó ṣáájú rẹ, o ṣe ọlọ́run míì fún ara rẹ àti àwọn ère onírin* láti mú mi bínú,+ o sì kẹ̀yìn sí mi.+ Nehemáyà 9:26 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 26 “Àmọ́, wọ́n ya aláìgbọràn, wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí ọ,+ wọ́n sì kẹ̀yìn sí Òfin rẹ.* Wọ́n pa àwọn wòlíì rẹ tó kìlọ̀ fún wọn láti mú wọn pa dà sọ́dọ̀ rẹ, wọ́n sì hu ìwà àìlọ́wọ̀ tó bùáyà.+ Àìsáyà 17:10 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 10 Torí o ti gbàgbé Ọlọ́run+ ìgbàlà rẹ;O ò rántí Àpáta+ ààbò rẹ. Ìdí nìyẹn tí o fi gbin àwọn ohun tó rẹwà,*Tí o sì fi ọ̀mùnú àjèjì* gbìn ín. Jeremáyà 2:32 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 32 Ǹjẹ́ wúńdíá lè gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀,Àbí ìyàwó lè gbàgbé ọ̀já ìgbàyà* rẹ̀? Síbẹ̀, àwọn èèyàn mi ti gbàgbé mi tipẹ́tipẹ́.+ Jeremáyà 13:25 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 25 Ìpín rẹ nìyí, ìpín tí mo wọ̀n fún ọ,” ni Jèhófà wí,“Nítorí pé o ti gbàgbé mi,+ o sì ń gba irọ́ gbọ́.+
9 Ohun tí o ṣe burú ju ti gbogbo àwọn tó ṣáájú rẹ, o ṣe ọlọ́run míì fún ara rẹ àti àwọn ère onírin* láti mú mi bínú,+ o sì kẹ̀yìn sí mi.+
26 “Àmọ́, wọ́n ya aláìgbọràn, wọ́n ṣọ̀tẹ̀ sí ọ,+ wọ́n sì kẹ̀yìn sí Òfin rẹ.* Wọ́n pa àwọn wòlíì rẹ tó kìlọ̀ fún wọn láti mú wọn pa dà sọ́dọ̀ rẹ, wọ́n sì hu ìwà àìlọ́wọ̀ tó bùáyà.+
10 Torí o ti gbàgbé Ọlọ́run+ ìgbàlà rẹ;O ò rántí Àpáta+ ààbò rẹ. Ìdí nìyẹn tí o fi gbin àwọn ohun tó rẹwà,*Tí o sì fi ọ̀mùnú àjèjì* gbìn ín.
32 Ǹjẹ́ wúńdíá lè gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀,Àbí ìyàwó lè gbàgbé ọ̀já ìgbàyà* rẹ̀? Síbẹ̀, àwọn èèyàn mi ti gbàgbé mi tipẹ́tipẹ́.+
25 Ìpín rẹ nìyí, ìpín tí mo wọ̀n fún ọ,” ni Jèhófà wí,“Nítorí pé o ti gbàgbé mi,+ o sì ń gba irọ́ gbọ́.+