Jeremáyà 46:25 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 25 “Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun, Ọlọ́run Ísírẹ́lì, sọ pé: ‘Wò ó, màá yíjú sí Ámọ́nì+ láti Nóò*+ àti sí Fáráò àti Íjíbítì àti àwọn ọlọ́run rẹ̀+ àti àwọn ọba rẹ̀, àní màá yíjú sí Fáráò àti gbogbo àwọn tí wọ́n gbẹ́kẹ̀ lé e.’+ Ìsíkíẹ́lì 29:3 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 3 Sọ pé: ‘Ohun tí Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ sọ nìyí: “Èmi yóò bá ọ jà, ìwọ Fáráò ọba Íjíbítì,+Ẹran ńlá inú àwọn odò Náílì* rẹ̀,+Tó sọ pé, ‘Èmi ni mo ni odò Náílì mi. Ara mi ni mo ṣe é fún.’+
25 “Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun, Ọlọ́run Ísírẹ́lì, sọ pé: ‘Wò ó, màá yíjú sí Ámọ́nì+ láti Nóò*+ àti sí Fáráò àti Íjíbítì àti àwọn ọlọ́run rẹ̀+ àti àwọn ọba rẹ̀, àní màá yíjú sí Fáráò àti gbogbo àwọn tí wọ́n gbẹ́kẹ̀ lé e.’+
3 Sọ pé: ‘Ohun tí Jèhófà Olúwa Ọba Aláṣẹ sọ nìyí: “Èmi yóò bá ọ jà, ìwọ Fáráò ọba Íjíbítì,+Ẹran ńlá inú àwọn odò Náílì* rẹ̀,+Tó sọ pé, ‘Èmi ni mo ni odò Náílì mi. Ara mi ni mo ṣe é fún.’+