24 Wọ́n máa fi ojú idà ṣá wọn balẹ̀, wọ́n á sì kó wọn lẹ́rú lọ sí gbogbo orílẹ̀-èdè;+ àwọn orílẹ̀-èdè* sì máa tẹ Jerúsálẹ́mù mọ́lẹ̀, títí àkókò tí a yàn fún àwọn orílẹ̀-èdè* fi máa pé.+
14 Àmọ́ a fún obìnrin náà ní ìyẹ́ méjèèjì ẹyẹ idì ńlá,+ kó lè fò lọ sí àyè rẹ̀ nínú aginjù, níbi tí wọ́n á ti máa bọ́ ọ fún àkókò kan àti àwọn àkókò àti ààbọ̀ àkókò*+ níbi tí ojú ejò náà+ ò tó.