ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 22:27
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 27 Gbogbo ayé á rántí, wọ́n á sì yíjú sọ́dọ̀ Jèhófà.

      Gbogbo ìdílé àwọn orílẹ̀-èdè á tẹrí ba níwájú rẹ.+

  • Àìsáyà 2:2, 3
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    •  2 Ní apá ìgbẹ̀yìn àwọn ọjọ́,*

      Òkè ilé Jèhófà

      Máa fìdí múlẹ̀ gbọn-in sórí àwọn òkè,+

      A sì máa gbé e ga ju àwọn òkè kéékèèké lọ,

      Gbogbo orílẹ̀-èdè á sì máa rọ́ lọ síbẹ̀.+

       3 Ọ̀pọ̀ èèyàn máa lọ, wọ́n á sì sọ pé:

      “Ẹ wá, ẹ jẹ́ ká lọ sórí òkè Jèhófà,

      Sí ilé Ọlọ́run Jékọ́bù.+

      Ó máa kọ́ wa ní àwọn ọ̀nà rẹ̀,

      A ó sì máa rìn ní àwọn ọ̀nà rẹ̀.”+

      Torí òfin* máa jáde láti Síónì,

      Ọ̀rọ̀ Jèhófà sì máa jáde láti Jerúsálẹ́mù.+

  • Sekaráyà 8:22, 23
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
    • 22 Ọ̀pọ̀ èèyàn àti orílẹ̀-èdè alágbára yóò wá sí Jerúsálẹ́mù láti wá Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun,+ kí wọ́n sì lè bẹ Jèhófà pé kó ṣojúure sí àwọn.’*

      23 “Ohun tí Jèhófà Ọlọ́run àwọn ọmọ ogun sọ nìyí, ‘Ní àwọn ọjọ́ yẹn, ọkùnrin mẹ́wàá láti inú gbogbo èdè àwọn orílẹ̀-èdè+ yóò di aṣọ* Júù* kan mú, àní wọn yóò dì í mú ṣinṣin, wọ́n á sì sọ pé: “A fẹ́ bá yín lọ,+ torí a ti gbọ́ pé Ọlọ́run wà pẹ̀lú yín.”’”+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́