ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w98 12/15 ojú ìwé 31
  • Atọ́ka Kókó Ẹ̀kọ́ Fún Ilé Ìṣọ́ 1998

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Kókó Ẹ̀kọ́ Fún Ilé Ìṣọ́ 1998
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
  • ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
  • BÍBÉLÌ
  • ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
  • ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
  • ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
  • JÈHÓFÀ
  • JÉSÙ KRISTI
  • LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
  • WỌ́N ṢE ÌFẸ́ JÈHÓFÀ
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
w98 12/15 ojú ìwé 31

Atọ́ka Kókó Ẹ̀kọ́ Fún Ilé Ìṣọ́ 1998

Ó ń tọ́ka sí ìtẹ̀jáde tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

Àpéjọpọ̀ “Ìgbàgbọ́ Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run,” 1/15

Àpéjọpọ̀ “Ọ̀nà Ìgbésí Ayé Tí Ọlọ́run Fẹ́,” 5/1, 9/1

Àwọn Dókítà, Adájọ́, àti Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà, 3/1

Ayẹyẹ Ìgbéyàwó Àrà Ọ̀tọ̀ (Mòsáńbíìkì), 6/15

Dídáàbò Bo Ìhìn Rere Lọ́nà Òfin, 12/1

“Ẹ Di Ohun Tí Ẹ Ní Mú Ṣinṣin” (Gíríìsì), 9/1

Ẹrú Ènìyàn Tàbí Ìránṣẹ́ Ọlọ́run? 3/15

Ẹ̀sìn Kristẹni Lẹ́nu Iṣẹ́—Láàárín Pákáǹleke, 1/15

Gbígbé Ẹ̀tọ́ Yíyàn Lárugẹ (Japan), 12/15

Gbígbé Ìtòsí Òkè Ayọnáyèéfín (Mexico), 8/15

Ìkẹ́kọ̀ọ́yege Ilé Ẹ̀kọ́ Gilead, 6/1, 12/1

Ìmújáde Ìwé Mímọ́ ní Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Lédè Yorùbá 7/15

Ìṣẹ̀lẹ̀ Mánigbàgbé Ní Ilẹ̀ Faransé, 7/1

Iṣẹ́ Tí “Kò Lè Ṣàìjèrè Ọ̀wọ̀” (Ítálì), 8/15

Ìwé Kan Tí Ó Wà fún Gbogbo Ènìyàn, Ìwé pẹlẹbẹ, 4/1

Láti Àwọn Ibùgbé Onílé Gogoro ní Àwọn Ìlú Ńlá Títí Dé Àgbègbè Aṣálẹ̀ Gbalasa (Kánádà), 4/15

Mímú Ìhìn Rere Dé Ọ̀dọ̀ Ènìyàn Púpọ̀ Sí I, 2/15

Nígbà Tí Àwọn Ọkàn Yíyigbì Bá Yí Padà (Poland), 10/15

“Ọlọ́run Nífẹ̀ẹ́ Olùfúnni Ọlọ́yàyà” (ìdáwó), 11/1

ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN

2/1, 3/1, 4/1, 6/1, 7/1, 8/1, 10/1, 11/1

BÍBÉLÌ

Àwọn Ọ̀mọ̀wé Sọ Déètì Mìíràn Tí A Kọ Bíbélì Àfọwọ́kọ, 12/15

“Bíbélì Oníka Kan,” 3/15

Ìtumọ̀ Tí Ó Yí Ayé Padà (Septuagint), 9/15

“Májẹ̀mú Tuntun Alápapọ̀ Èdè Méjì Dídára Jù Lọ,” 2/1

Ǹjẹ́ O Lè Gba Bíbélì Gbọ́? 10/15

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

Ìdí tí àwọn àpọ́sítélì kò fi lè wo ọmọdékùnrin kan sàn (Mt 17:20; Mk 9:29), 8/1

Lúùkù 13:24, 6/15

Ṣíṣe àyájọ́ ayẹyẹ ìgbéyàwó, ọjọ́ ìbí, 10/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

Àṣà Ìsìnkú, 7/15

Àwọn Àṣà Ìbílẹ̀ àti Àwọn Ìlànà Kristẹni, 10/1

Bọlá fún Iyì Wọn, 4/1

Dáàbò Bo Àwọn Ọmọ Rẹ, 7/15

Ẹ̀yin Òbí—Ẹ Dáàbò Bo Àwọn Ọmọ Yín! 2/15

Fi Ohun Tí Ó Ṣe Pàtàkì Jù Ṣáájú! 9/1

Gbádùn Ayé Rẹ, 8/15

Gbígbé Àǹfààní Iṣẹ́ Ìsìn Mímọ́ Gẹ̀gẹ̀, 8/1

Ìmoore, 2/15

Kíkẹ́kọ̀ọ́ Láti Inú Àṣìṣe Àtẹ̀yìnwá, 7/1

Máa Tẹ̀ Síwájú Nípa Tẹ̀mí! 10/1

Ìwọ Ha Mọrírì Àwọn Ìbùkún Jèhófà Bí? 1/1

Ó Ha Yẹ Kí N Yáwó Lọ́wọ́ Arákùnrin Mi Bí? 11/15

O Lè Tẹ̀ Síwájú Nípa Tẹ̀mí, 5/15

Owó Orí Ìyàwó, 9/15

“Ọkàn-Àyà Ìgbọràn,” 7/15

Ọnà Ìyíniléròpadà, 5/15

Ṣé Ìyìn Ni Tàbí Ìpọ́nni? 2/1

Ṣọ́ra fún Ríra Ipò! 11/15

Títẹ́wọ́gba Ẹrù Iṣẹ́ Bíbójútó Ìdílé, 6/1

Wíwéwèé Ṣáájú fún Àwọn Olólùfẹ́ Wa, 1/15

Yanjú Ìṣòro ní Ìtùnbí-Ìnùbí, 11/1

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

A Mú Un Dúró La Ọ̀pọ̀ Àdánwò Lílekoko Já (É. Josefsson), 6/1

Ìgbésí Ayé Mi Gẹ́gẹ́ Bí Adẹ́tẹ̀ (I. Adagbona), 4/1

“Inú Rere Rẹ Onífẹ̀ẹ́ Sàn Ju Ìyè” (C. H. Holmes), 2/1

Iṣẹ́ Àyànfúnni Yí Padà Ní Ẹni 80 Ọdún (G. Matthews), 5/1

Kò Sí Ohun Tí Ó Dára Bí Òtítọ́ (G. N. Van der Bijl), 1/1

Látorí Ìjọsìn Olú Ọba sí Ìjọsìn Tòótọ́ (I. Sugiura), 12/1

Mo Dúpẹ́ fún Ogún Kristẹni (G. Gooch), 3/1

Mo Kọ́ Láti Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà (J. Korpa-Ondo), 9/1

Mo Rí Ohun Tó Sàn Ju Wúrà Lọ (C. Mylton), 10/1

“Ohun Tí Ó Yẹ Kí A Ṣe Ni A Ṣe” (G. Couch), 8/1

Wíwu Jèhófà Ni Olórí Àníyàn Mi (T. Neros), 11/1

JÈHÓFÀ

Ó Ha Jẹ́ Ẹni Gidi Sí Ọ Bí? 9/15

Ta Ni Jèhófà? 5/1

JÉSÙ KRISTI

Àwọn Ọjọ́ Tó Lò Kẹ́yìn Lórí Ilẹ̀ Ayé, 3/15

Ìbí Rẹ̀, 12/15

Ìpìlẹ̀ fún Ojúlówó Ìgbàgbọ́, 12/1

Olùṣàkóso “Tí Orírun Rẹ̀ Jẹ́ Láti Àwọn Àkókò Ìjímìjí,” 6/15

LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

A Kórìíra Wọn Nítorí Ìgbàgbọ́ Wọn, 12/1

A Mú Ìdájọ́ Ṣẹ Ní Pẹ̀tẹ́lẹ̀ Rírẹlẹ̀ Ti Ìpinnu, 5/1

A Óò Dán Ìgbàgbọ́ Kristẹni Wò, 5/15

‘A Óò Gbé Àwọn Òkú Dìde,’ 7/1

Àwọn Àgùntàn Mìíràn àti Májẹ̀mú Tuntun, 2/1

Àwọn Àjọyọ̀ Mánigbàgbé Inú Ìtàn Ísírẹ́lì, 3/1

Báwo Ni Ìgbàgbọ́ Rẹ Nínú Àjíǹde Ti Lágbára Tó? 7/1

Bíbá Ọlọ́run Rìn—Àwọn Ìgbésẹ̀ Àkọ́kọ́, 11/15

Bíbá Ọlọ́run Rìn—Pẹ̀lú Ayérayé Lọ́kàn, 11/15

Dídúró Pẹ̀lú “Ìfojúsọ́nà Oníhàáragàgà,” 9/15

Ètò Àjọ Jèhófà Ń Ti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Rẹ Lẹ́yìn, 6/15

‘Ẹ Máa Bá A Lọ ní Rírìn ní Ìrẹ́pọ̀ Pẹ̀lú Kristi,’ 6/1

Ẹ Máa Bá A Nìṣó Ní Bíbá Ọlọ́run Rìn, 1/15

Ẹ Máa Ṣiṣẹ́ Ìgbàlà Yín Yọrí! 11/1

Ẹ Má Ṣe Juwọ́ Sílẹ̀ Nínú Eré Ìje fún Ìyè! 1/1

Fara Mọ́ Ìṣàkóso Ọlọ́run Tímọ́tímọ́, 9/1

Fara Wé Àánú Jèhófà, 10/1

Fara Wé Jèhófà—Máa Ṣe Òdodo àti Ìdájọ́ Òdodo, 8/1

Fífún Ìgbọ́kànlé Wa Nínú Òdodo Ọlọ́run Lókun, 8/15

Gbígbèjà Ìgbàgbọ́ Wa, 12/1

Gbígbé Ní Ìbámu Pẹ̀lú Ìyàsímímọ́ Kristẹni ní Òmìnira, 3/15

Ìbùkún Púpọ̀ Sí I Nípasẹ̀ Májẹ̀mú Tuntun, 2/1

Ìgbà àti Àsìkò Wà Lọ́wọ́ Jèhófà, 9/15

Ìgbàgbọ́ àti Ọjọ́ Ọ̀la Rẹ, 4/15

Ìjójúlówó Ìgbàgbọ́ Rẹ—A Ń Dán An Wò Nísinsìnyí, 5/15

“Ikú Ni A Ó Sọ Di Asán,” 7/1

Ìwé Kan Tí Ó Wà fún Gbogbo Ènìyàn, 4/1

Ìwé Kan Tí Ó Wá Láti Ọ̀dọ̀ Ọlọ́run, 4/1

Ìyàsímímọ́ àti Òmìnira Ṣíṣe Yíyàn, 3/15

“Jèhófà, Ọlọ́run Aláàánú àti Olóore Ọ̀fẹ́,” 10/1

Jèhófà Jẹ́ Ọlọ́run Májẹ̀mú, 2/1

Jèhófà Ni Ó Yẹ Kí A Gbọ́kàn Lé, 8/15

Jèhófà Ń Mú Ìlérí Rẹ̀ Ṣẹ fún Àwọn Olùṣòtítọ́, 4/15

Jèhófà Ń Mú Ọ̀pọ̀ Ọmọ Wá Sínú Ògo, 2/15

Jèhófà—Orísun Òdodo àti Ìdájọ́ Òdodo, 8/1

Jerúsálẹ́mù—“Ìlú Ńlá ti Ọba Ńlá Náà,” 10/15

Jerúsálẹ́mù Kan Tí Orúkọ Rò, 10/15

Jerúsálẹ́mù—Ó Ha ‘Ré Kọjá Olórí Ìdí Tí O Ní fún Ayọ̀ Yíyọ̀ Bí’? 10/15

“Máa Ja Ìjà Líle fún Ìgbàgbọ́”! 6/1

Mímọrírì Àwọn Ìpéjọpọ̀ Kristẹni, 3/1

“Nípa Ìgbàgbọ́ Ni Àwa Ń Rìn, Kì Í Ṣe Nípa Ohun Tí A Rí,” 1/15

O Ha Mọyì Ètò Àjọ Jèhófà Bí? 6/15

O Ha Ti Wọnú Ìsinmi Ọlọ́run Bí? 7/15

Òmìnira Ológo fún Àwọn Ọmọ Ọlọ́run Láìpẹ́, 2/15

Ọjọ́ Ìgbàlà Nìyí! 12/15

Ọjọ́ Jèhófà Sún Mọ́lé, 5/1

“Ọkàn Àyà Rẹ Ha Dúró Ṣánṣán Pẹ̀lú Mi Bí?” 1/1

Ṣé Iṣẹ́ Rẹ Yóò La Iná Já? 11/1

Ṣọ́ra fún Àìnígbàgbọ́, 7/15

Ta Ni Yóò “Yè Bọ́”? 5/1

Ti Jèhófà Ni Ìgbàlà, 12/15

Wà Láìséwu Gẹ́gẹ́ Bí Apá Kan Ètò Àjọ Ọlọ́run, 9/1

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

Àìní Ìgbọ́kànlé Ń Gbilẹ̀, 8/15

A Óò Ha Máa Fìgbà Gbogbo Nílò Ẹgbẹ́ Ọmọ Ogun Bí? 4/15

Àwọn Alátùn-únṣe, 8/15

Àwọn Ènìyàn “Tí Ó Ní Ìmọ̀lára Bí Tiwa,” 3/1

Àwọn Ìsìn Ń Tọrọ Àforíjì, 3/1

Àwọn Maccabee, 11/15

Bánábà—“Ọmọ Ìtùnú,” 4/15

Bẹ́tẹ́lì—Ìlú Ohun Rere àti Búburú, 9/1

Bí Àwọn Áńgẹ́lì Ṣe Lè Ràn Ọ́ Lọ́wọ́, 11/15

Constantine Ńlá, 3/15

Dáríúsì, 11/15

Èé Ṣe Tí Wọ́n Fi Ń Fi Ìsìn Sílẹ̀? 7/1

Ẹ̀mí Nǹkan-Yóò-Dára Tàbí Iyèméjì? 2/1

Fílémónì àti Ónẹ́símù, 1/15

Ìdájọ́ Òdodo fún Kóówá, 8/1

Ìdájọ́ Òdodo—Nígbà Wo àti Lọ́nà Wo? 6/15

Ìdílé Wà Nínú Ewu, 4/1

Ilẹ̀ Ayé—Èé Ṣe Tí Ó Fi Wà Níhìn-ín? 6/15

Jíjọ́sìn Ọlọ́run ní Òtítọ́, 10/1

Mú Sùúrù, 6/1

Nígbà Tí Àwọn Adigunjalè Bá Ṣọṣẹ́, 12/15

Ǹjẹ́ Gbogbo Àlùfáà Gba Ohun Tí Wọ́n Ń Kọ́ni Gbọ́? 10/15

Ǹjẹ́ Ìkú Tí Ń Pa Aráyé Ló Pa Màríà? 8/1

Ǹjẹ́ Kérésìmesì Kò Ti Jẹ́ Ká Gbàgbé Kristi? 12/15

Ǹjẹ́ O Lè Fi Ìyàtọ̀ Sáàárín Ohun Tí Ó Tọ́ àti Ohun Tí Kò Tọ́? 9/1

Ǹjẹ́ O Lè Gbára Lé Ẹ̀rí-Ọkàn Rẹ? 9/1

Ǹjẹ́ O Lóye Ìgbà Tí A Wà Yìí? 9/15

Onígbèéraga Adelé Ọba Kan Pàdánù Ilẹ̀ Ọba Kan (Bẹliṣásárì), 9/15

Òòfà Agbára Ìdánilọ́rùn—Iyì Ènìyàn Tàbí Ògo Ọlọ́run? 2/15

Òtítọ́ Ń Yí Ìgbésí Ayé Pa Dà, 1/1

‘Òtítọ́ Yóò Dá Yín Sílẹ̀ Lómìnira,’ 10/1

Ọjọ́ Ọ̀la Wa Ha Ti Wà Nínú Àkọọ́lẹ̀ Bí? 4/15

Ọrọ̀ Ha Lè Mú Ọ Láyọ̀ Bí? 5/15

“Sọ Àwọn Ènìyàn Gbogbo Orílẹ̀-Èdè Di Ọmọ-Ẹ̀yìn,” 1/1

Ṣé Àìṣèdájọ́ Òdodo Kò Ṣeé Yẹ̀ Sílẹ̀ Ni? 8/1

Ṣé Ilẹ̀ Ayé Fẹ́ Parẹ́ Ni? 6/15

Ṣọ́ra fún Àwọn Olùyọṣùtì! 6/1

Talmud, 5/15

Ta Ní Ń Bẹ Lẹ́yìn Gbogbo Rẹ̀? 5/1

Tíkíkù, 7/15

Títù, 11/15

Wọn Kò Ṣe Orúkọ Lílókìkí fún Ara Wọn, 3/15

Yùníìsì àti Lọ́ísì, 5/15

WỌ́N ṢE ÌFẸ́ JÈHÓFÀ

Ará Samáríà Kan Jẹ́ Aládùúgbò Rere, 7/1

A San Èrè fún Ìwà Títọ́ Jóòbù, 5/1

Èlíjà Gbé Ọlọ́run Tòótọ́ Ga, 1/1

Jésù Rán 70 Ọmọ Ẹ̀yìn Jáde, 3/1

Jésù Wá Àyè Gbọ́ ti Àwọn Ọmọdé, 11/1

Pọ́ọ̀lù Fìgboyà Wàásù, 9/1

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́