ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w15 12/15 ojú ìwé 32
  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2015

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2015
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2015
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2015
w15 12/15 ojú ìwé 32

Atọ́ka Àwọn Àkòrí Ilé Ìṣọ́ 2015

Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde

ÀWỌN ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

  • A Lè Jẹ́ Oníwà Mímọ́, 6/15

  • Àwọn Ọ̀nà Wo Ni Jèhófà Ń Gbà Fìfẹ́ Hàn sí Wa? 9/15

  • Bá A Ṣe Lè Fi Kún Ẹwà Párádísè Tẹ̀mí, 7/15

  • Báwo La Ṣe Lè Fi Hàn Pé A Nífẹ̀ẹ́ Jèhófà? 9/15

  • Bí Àwọn Alàgbà Ṣe Ń Kọ́ Àwọn Míì Kí Wọ́n Lè Tóótun, 4/15

  • Bíbélì Tó Rọrùn Láti Lóye, 12/15

  • Bí Tọkọtaya Ṣe Lè Ṣera Wọn Lọ́kan Kí Wọ́n sì Láyọ̀, 1/15

  • Èyí Ni “Ọ̀nà Tí Ìwọ Tẹ́wọ́ Gbà,” 3/15

  • ‘Ẹ Dúró Gbọn-in Nínú Ìgbàgbọ́,’ 9/15

  • Ẹ Fara Wé Ẹni Tó Ṣèlérí Ìyè Àìnípẹ̀kun, 5/15

  • Ẹ Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà Nígbà Gbogbo! 4/15

  • Ẹ Jẹ́ Onígboyà Kẹ́ Ẹ sì Máa Lo Ìfòyemọ̀ Bíi Ti Jésù, 2/15

  • Ẹ Jẹ́ Onírẹ̀lẹ̀ àti Oníjẹ̀lẹ́ńkẹ́ Bíi Ti Jésù, 2/15

  • Ẹ Máa Bá A Nìṣó ní Fífojú Sọ́nà, 8/15

  • Ẹ̀yin Alàgbà, Ǹjẹ́ Ẹ Máa Ń Dá Àwọn Míì Lẹ́kọ̀ọ́? 4/15

  • Fi Ọpẹ́ Fún Jèhófà Kí O sì Gba Ìbùkún, 1/15

  • “Fún Wa Ní Ìgbàgbọ́ Sí I,” 10/15

  • Ibi Ìjọsìn Wa Rèé, 7/15

  • “Ìdáǹdè Yín Ń Sún Mọ́lé”! 7/15

  • Ìdí Tí A Fi Ń Lọ Síbi Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa, 1/15

  • Jèhófà Máa Ń Bá Àwa Èèyàn Sọ̀rọ̀, 12/15

  • Jèhófà Ń Darí Iṣẹ́ Ìkọ́nilẹ́kọ̀ọ́ Tí À Ń Ṣe Kárí Ayé, 2/15

  • Jèhófà Yóò Gbé Ọ Ró, 12/15

  • Jẹ́ Adúróṣinṣin sí Ìjọba Ọlọ́run, 7/15

  • Jẹ́ Kí Jèhófà Dáàbò Bo Ìgbéyàwó Rẹ Kó sì Fún Un Lókun, 1/15

  • Kẹ́kọ̀ọ́ Látinú Àpèjúwe Nípa Àwọn Tálẹ́ńtì Náà, 3/15

  • Kọ́ Ọmọ Rẹ Kó Lè Sin Jèhófà, 11/15

  • Kristi​—Agbára Ọlọ́run, 6/15

  • Máa Fi Ahọ́n Rẹ Sọ̀rọ̀ Tó Ń Gbéni Ró, 12/15

  • Máa Fi Ìdúróṣinṣin Ti Àwọn Arákùnrin Kristi Lẹ́yìn, 3/15

  • Máa Gbé Ìgbé Ayé Rẹ Ní Ìbámu Pẹ̀lú Àdúrà Àwòṣe Náà, 6/15

  • Máa Gbé Ìgbé Ayé Tó O Máa Gbé Nínú Ayé Tuntun Báyìí, 8/15

  • Máa Ṣàṣàrò Lórí Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, 10/15

  • Máa Ṣe Àṣàrò Lórí Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Tí Jèhófà Ní sí Wa, 8/15

  • Mímúra Àwọn Orílẹ̀-Èdè Sílẹ̀ fún “Ẹ̀kọ́ Jèhófà,” 2/15

  • Ǹjẹ́ Ìfẹ́ Àárín Tọkọtaya Lè Wà Pẹ́ Títí? 1/15

  • Ǹjẹ́ Ó Dá Ẹ Lójú Pé O Ní Àjọṣe Tó Dán Mọ́rán Pẹ̀lú Jèhófà? 4/15

  • Ǹjẹ́ Ò Ń Dé Ìwọ̀n Ìdàgbàsókè Tó Jẹ́ Ti Kristi? 9/15

  • Ǹjẹ́ O “Nífẹ̀ẹ́ Aládùúgbò Rẹ Gẹ́gẹ́ Bí Ara Rẹ”? 11/15

  • Ǹjẹ́ Ò Ń Rí Ọwọ́ Ọlọ́run Nínú Ìgbésí Ayé Rẹ? 10/15

  • O Lè Bá Sátánì Jà​—Kó o sì Borí! 5/15

  • Ó Nífẹ̀ẹ́ Àwọn Èèyàn, 6/15

  • Ọgọ́rùn-ún Ọdún Tí Ìjọba Ọlọ́run Ti Bẹ̀rẹ̀ Sí Í Ṣàkóso! 11/15

  • Ọlọ́run Ìfẹ́ Ni Jèhófà, 11/15

  • Sin Jèhófà Láìsí Ìpínyà Ọkàn, 10/15

  • Ṣé Ẹ̀rí Ọkàn Rẹ Ṣeé Gbára Lé? 9/15

  • Ṣé Wàá “Máa Bá A Nìṣó Ní Ṣíṣọ́nà”? 3/15

  • Ṣọ́ Àwọn Tó Ò Ń Bá Kẹ́gbẹ́ ní Àwọn Ọjọ́ Ìkẹyìn Yìí, 8/15

  • Ṣọ́ra!​—Sátánì Fẹ́ Pa Ọ́ Jẹ 5/15

  • Wọ́n “Rí” Àwọn Ohun Tí Ọlọ́run Ṣèlérí, 5/15

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ

  • “Àkókò Tá A Mọyì Jù Lọ” (Ìrántí Ikú Kristi), 2/15

  • ‘Ẹ Máa Ka Irú Àwọn Ènìyàn Bẹ́ẹ̀ Sí Ẹni Ọ̀wọ́n’ (àwọn tó ń ṣèrànwọ́ fún Ìgbìmọ̀ Olùdarí), 10/15

  • Ìdí Tí Ìyọlẹ́gbẹ́ Fi Jẹ́ Ìpèsè Onífẹ̀ẹ́, 4/15

  • Ìfẹ́ Mú Kí Nǹkan Wà Létòletò Nílé Ìjẹun, 5/15

  • “Jèhófà Mú Yín Wá sí Ilẹ̀ Faransé Láti Kẹ́kọ̀ọ́ Òtítọ́” (àwọn ọmọ orílẹ̀-èdè Poland tó wá sí ilẹ̀ Faransé lẹ́yìn Ogun Àgbáyé Kìíní), 8/15

  • Mọrírì Ìwà Ọ̀làwọ́ Jèhófà (ọrẹ), 11/15

  • ‘Ohunkóhun Ò Gbọ́dọ̀ Dí Yín Lọ́wọ́!’ (àwọn apínwèé-ìsìn-kiri nílẹ̀ Faransé), 11/15

  • Ta Ni Àwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà? 9/1

  • “Tí Kingsley Bá Lè Ṣe É, Èmi Náà Lè Ṣe É!” 6/15

  • Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn​—Ní New York, 1/15

  • Wọ́n Yọ̀ǹda Ara Wọn​—Ní Rọ́ṣíà, 7/15

BÍBÉLÌ

  • Àsọtẹ́lẹ̀, 9/1

  • Bíbélì Bedell (Ireland), 9/1

  • Ẹ̀bùn Pàtàkì Kan Tó Wà fún Àwọn Ará Japan (Mátíù), 2/15

  • Ìwé Mímọ́ ní Ìtumọ̀ Ayé Tuntun Tá A Tún Ṣe Lọ́dún 2013, 12/15

  • Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Ṣàyẹ̀wò? 2/1

  • Ohun Iyebíye Tí Wọ́n Rí Nínú Pàǹtírí (àjákù òrépèté Rylands), 4/1

  • O Lè Lóye, 12/1

  • Ṣé Ìmọ̀ Sáyẹ́ǹsì ti Rọ́pò? 6/1

  • Ṣé Wàá Fẹ́ Kẹ́kọ̀ọ́? 4/1

BÍBÉLÌ MÁA Ń YÍ ÌGBÉSÍ AYÉ ÀWỌN ÈÈYÀN PA DÀ

  • Bíbélì Dáhùn Gbogbo Ìbéèrè Mi (M. Gündel), 1/1

  • Ìbéèrè Mẹ́ta Ló Yí Ìgbésí Ayé Mi Pa Dà (D. Eldred), 4/1

  • Ìdáhùn sí Àwọn Ìbéèrè Pàtàkì Nígbèésí Ayé (E. Loedi), 2/1

  • Ìwà Búburú Ọwọ́ Mi Ń Peléke Sí I (S. McDowell), 7/1

  • Mo Kẹ́kọ̀ọ́ Pé Jèhófà Jẹ́ Aláàánú (N. Pelletier), 5/1

  • Mo Rò Pé Mò Ń Jayé Orí Mi Ni (P. Pyzara), 11/1

  • Mo Ti Lè Ran Àwọn Míì Lọ́wọ́ Báyìí (J. Corio), 10/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

  • Àpẹẹrẹ àti ìmúṣẹ, 3/15

  • Àwọn ará wa tí lọ́fíńdà máa ń gbòdì lára wọn, 2/15

  • Kí ló fi hàn pé kò pẹ́ táwọn ọmọ Ísírẹ́lì dó ti Jẹ́ríkò tí wọ́n fi ṣẹ́gun rẹ̀? 11/15

  • Ǹjẹ́ àwọn ìwé ìtàn jẹ́rìí sí i pé Pọ́ńtíù Pílátù gbé láyé rí? 2/15

  • Ǹjẹ́ ó yẹ kí arábìnrin kan borí rẹ̀ tó bá ń darí ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì? 2/15

  • Ta ni Gọ́ọ̀gù ti ilẹ̀ Mágọ́gù? 5/15

ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI

  • Àǹfààní Wo Lo Máa Rí Tó O Bá Ń Gbàdúrà? 10/1

  • “Ẹ Nílò Ìfaradà,” 6/15

  • Ẹ̀yin Ọkọ​—⁠Ẹ Mú Kí Ilé Yín Tura, 1/1

  • Gbádùn Iṣẹ́ Rẹ, 2/1

  • Gbéyàwó “Kìkì Nínú Olúwa”​—Ǹjẹ́ Ó ṣì Bọ́gbọ́n Mu? 3/15

  • Jọ́sìn Jèhófà ní “Àwọn Ọjọ́ Oníyọnu,” 7/15

  • Máa Dárí Jini Látọkànwá, 10/1

  • Máa Fi Ìtara Wàásù Nìṣó, 2/15

  • Ǹjẹ́ Ó Ṣe Pàtàkì Pé Kí Àwọn Èèyàn Rí Ohun Tó O Bá Ṣe? 7/15

  • “Òpè Eniyan A Máa Gba Ohun Gbogbo Gbọ́,” 10/15

ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ

  • Ìbùkún Jèhófà Mú Kí Ìgbésí Ayé Mi Túbọ̀ Nítumọ̀ (M. Jaracz), 9/15

  • Ìfẹ́ Tí Mo Ní fún Ọlọ́run Látìbẹ̀rẹ̀ (A. Morris III), 5/15

  • Ìpinnu Tó Ṣe Nígbà Èwe Rẹ̀ (N. Dubovinsky), 10/15

  • Ìran Méje Tó Sin Jèhófà (K. Williams), 6/1

  • Jèhófà Fi Àánú Hàn sí Mi Ju Bí Mo Ṣe Rò Lọ (F. Alarcón), 8/1

  • “Kí Ọ̀pọ̀lọpọ̀ Erékùṣù Máa Yọ̀” (G. Jackson), 8/15

  • Mo Ní Àjọṣe Tó Dáa Pẹ̀lú Ọlọ́run àti Pẹ̀lú Màmá Mi (M. Kumagai), 12/15

  • Ohun Míì Tó Sàn Jù Tá A Fi Ìgbésí Ayé Wa Ṣe (D. àti G. Cartwright), 3/15

  • Ohun Tó Sàn Ju Òkìkí (M. H. Godenzi), 9/1

  • Ojú Jairo Mú Kó Lè Sin Ọlọ́run, 3/1

  • Ọ̀pọ̀ Ìbùkún Ní “Àsìkò Tí Ó Rọgbọ àti Ní Àsìkò Tí Ó Kún Fún Ìdààmú” (T. R. Nsomba), 4/15

  • Sísún Mọ́ Ọlọ́run Dára fún Mi (S. Maiga), 10/15

JÈHÓFÀ

  • Èrò Ọlọ́run Nípa Ogun, 11/1

  • Ǹjẹ́ A Lè Mọ Ọlọ́run? 10/1

  • Ǹjẹ́ A Lè Mú Inú Ọlọ́run Dùn? 7/1

  • Ohun Tó Jẹ́ Òtítọ́ Nípa Ọlọ́run, 12/1

  • Ṣé O Ronú Pé Ọlọ́run Ti Já Ẹ Kulẹ̀? 9/1

JÉSÙ KRISTI

  • Jésù Gbà Wá​—Lọ́wọ́ Kí Ni? 3/1

  • Ká Máa Rántí Ikú Jésù, 3/1

  • Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Ṣe Ìrántí Ikú Jésù? 4/1

  • Ṣé Jésù Ló Yẹ Ká Máa Gbàdúrà Sí? 1/1

Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN

  • Àníyàn, 7/1

  • Aṣòdì sí Kristi, 6/1

  • Àwọn Kìnnìún Kú Tán ní Agbègbè Ísírẹ́lì, 5/1

  • Balógun Ọgọ́rùn-ún Nínú Ẹgbẹ́ Ọmọ Ogun Róòmù, 4/1

  • Báwo Lo Ṣe Lè Jẹ́ Òbí Rere? 6/1

  • Báwo Ni Ìwà Ìmọtara-Ẹni-Nìkan Ṣe Máa Dópin? 4/1

  • Bí Wọ́n Ṣe Ń Sanwó Iṣẹ́ fún Àwọn Olùṣọ́ Àgùntàn, 3/1

  • Bó O Ṣe Lè Dàgbà Lọ́nà Tó Ń Yẹni, 6/1

  • Bó O Ṣe Lè Tọ́ Àwọn Ọmọ Rẹ Yanjú, 6/1

  • Dígí Láyé Ìgbà Tí Wọ́n Ń Kọ Bíbélì, 4/1

  • “Èmi Ha Wà ní Ipò Ọlọ́run Bí?” (Jósẹ́fù), 5/1

  • Ẹ̀bùn Tó Tọ́ Sí Ọba (èròjà atasánsán), 3/1

  • Ẹlẹ́dàá Wà, 1/1

  • Gbogbo Ayé Lábẹ́ Ìjọba Kan Ṣoṣo, 2/1

  • Ibi Táwọn Èèyàn Ń Sùn Sí Nígbà Àjọyọ̀ Àwọn Júù, 12/1

  • Ìdí Táwọn Aráàlú Málítà Fi Ronú Pé Apààyàn Ni Àpọ́sítélì Pọ́ọ̀lù, 10/1

  • Ìdí Tí Jósẹ́fù Fi Fa Irun Rẹ̀ Kó Tó Lọ Rí Fáráò, 11/1

  • Ìjọba Tó Máa Fòpin Sí Ìwà Ìbàjẹ́, 1/1

  • “Ipò Oókan Àyà,” 7/1

  • “Ìtúmọ̀ Kò Ha Jẹ́ Ti Ọlọ́run?” (Jósẹ́fù), 2/1

  • Ìwẹ̀fà, 1/1

  • Jíjẹ́ Ọmọ Ìbílẹ̀ Róòmù, 3/1

  • Kí La Lè Rí Kọ́ Látinú Àpẹẹrẹ Jòánà? 8/15

  • Kí Nìdí Tá A Fi Wà Láyé? 8/1

  • Kí Nìdí Tí Àwọn Èèyàn Fi Ń Hùwà Ibi? 7/1

  • Kí Nìdí Tí Ọlọ́run Fi Dá Èèyàn? 8/1

  • ‘Mo Dìde Gẹ́gẹ́ Bí Ìyá ní Ísírẹ́lì’ (Dèbórà), 8/1

  • Ǹjẹ́ Àwárí Àwọn Awalẹ̀pìtàn Bá Àkọsílẹ̀ Bíbélì Mu? 5/1

  • Ǹjẹ́ Ìṣẹ́ àti Òṣì Lè Dópin Láyé? 10/1

  • Ǹjẹ́ Òpin Ti Sún Mọ́lé? 5/1

  • Olùṣọ́ Àgùntàn Ya Àgùntàn Sọ́tọ̀ Lára Àwọn Ewúrẹ́, 1/1

  • Ọdún Kérésì, 12/1

  • Ọjọ́ Ìdájọ́, 5/1

  • Ọjọ́ Ọ̀la Àwa Èèyàn, 4/1

  • Ọlọ Ọlọ́wọ́ Láyé Àtijọ́, 7/1

  • “Ọmọ Mi Olùfẹ́ Ọ̀wọ́n àti Olùṣòtítọ́” (Tímótì), 11/1

  • Ṣé Àwọn Òkú Máa Jíǹde? Ibo Làwọn Òkú Máa Jíǹde Sí? 11/1

  • Ṣé Àwọn Tó Ti Kú Lè Jíǹde? 8/1

  • Ṣé Igi Tí Wọ́n Gé Lulẹ̀ Tún Lè Hù Pa Dà? 4/15

  • Ṣé Igbó Kìjikìji Pọ̀ ní Ilẹ̀ Ísírẹ́lì Àtijọ́? 7/15

  • Ṣé Ìwà Àgàbàgebè Lè Dópin? 12/1

  • Ṣé “Láti Gbogbo Orílẹ̀-Èdè” Ni Àwọn Júù Ti Wá Sí Pẹ́ńtíkọ́ọ̀sì Ọdún 33 Sànmánì Kristẹni? 12/1

  • Ṣé Ó Yẹ Kí Àwọn Kristẹni Máa Ṣe Ayẹyẹ Ọdún Àjíǹde? 3/1

  • Ṣé Ọmọ Ìbílẹ̀ Gíríìsì ni Bàbá Tímótì? 11/1

  • Ṣé Pétérù ni Póòpù Àkọ́kọ́? 12/1

  • Tẹ́ńpìlì Hẹ́rọ́dù, 10/1

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́