ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • km 6/05 ojú ìwé 6
  • Kíyè sí Àsọtẹ́lẹ̀ Dáníẹ́lì!

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Kíyè sí Àsọtẹ́lẹ̀ Dáníẹ́lì!
  • Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2005
Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2005
km 6/05 ojú ìwé 6

Kíyè sí Àsọtẹ́lẹ̀ Dáníẹ́lì!

Ìtòlẹ́sẹẹsẹ ìkẹ́kọ̀ọ́ ti ọ̀sẹ̀ June 27, 2005, sí ọ̀sẹ̀ April 10, 2006.

Ọ̀SẸ̀ TI ORÍ ÀWỌN ÌPÍNRỌ̀ ẸSẸ TÍ ÌKẸ́KỌ̀Ọ́ DÁ LÉ

June 27 1 1 sí 18

July 4 2 1 sí 15

11 2 16 sí 32

18 3 1 sí 14 Dán. 1:1-7

25 3 15 sí 26 Dán. 1:8-15

Aug. 1 3 27 sí 37 Dán. 1:16-21

8 4 1 sí 11 Dán. 2:1-39

15 4 12 sí 24* Dán. 2:39, 40

22 4 25 sí 36 Dán. 2:41-49

29 5 1 sí 17 Dán. 3:1-18

Sept. 5 5 18 sí 25* Dán. 3:19-30

12 6 1 sí 14 Dán. 4:1-27

19 6 15 sí 29 Dán. 4:28-37

26 7 1 sí 16 Dán. 5:1-23

Oct. 3 7 17 sí 28 Dán. 5:24-31

10 8 1 sí 16 Dán. 6:1-17

17 8 17 sí 29 Dán. 6:18-28

24 9 1 sí 12 Dán. 7:1-5

31 9 13 sí 19 Dán. 7:6, 7

Nov. 7 9 20 sí 32 Dán. 7:8

14 9 33 sí 40 Dán. 7:9-28

21 10 1 sí 15 Dán. 8:1-8

28 10 16 sí 30 Dán. 8:9-27

Dec. 5 11 1 sí 12 Dán. 9:1-23

12 11 13 sí 20 Dán. 9:24, 25

19 11 21 sí 30 Dán. 9:26, 27

26 12 1 sí 13 Dán. 10:1-8

Jan. 2 12 14 sí 22 Dán. 10:9-21

9 13 1 sí 15 Dán. 11:1-4

16 13 16 sí 30 Dán. 11:5-16

23 13 31 si 39 Dán. 11:17-19

30 14 1 sí 15 Dán. 11:20-24

Feb. 6 14 16 sí 27 Dán. 11:25, 26

13 15 1 sí 15 Dán. 11:27-30a

20 15 16 sí 25 Dán. 11:30b, 31

27 16 1 sí 17 Dán. 11:32-41

Mar. 6 16 18 sí 28 Dán. 11:42-45

13 17 1 sí 12 Dán. 12:1-3

20 17 13 sí 23 Dán. 12:4-11

27 17 24 sí 29 Dán. 12:12

Apr. 3 18 1 sí 12 Dán. 12:13

10 18 13 sí 27 Dán. 12:13

Ẹ jíròrò àfikún àlàyé nígbà tẹ́ ẹ bá dé ibi ìpínrọ̀ tàbí ìbéèrè èyíkéyìí tá a ti tọ́ka sí irú àlàyé bẹ́ẹ̀. Bí àpẹẹrẹ, bẹ́ ẹ bá dé orí 2, ìpínrọ̀ 25, ìbéèrè (d), ẹ jíròrò àpótí náà “Ọ̀ràn Èdè.” (Àpótí yìí wà lójú ìwé 26.) Ẹ jíròrò àwọn àtẹ àti àwòrán tó wà nínú ìwé náà nígbà tẹ́ ẹ bá kẹ́kọ̀ọ́ débi tí wọ́n wà. Lẹ́yìn tẹ́ ẹ bá ti ka ìpínrọ̀ tó yẹ kẹ́ ẹ kà lọ́sẹ̀ kan tán, bí àkókò bá wà, ẹ jíròrò “ẹsẹ tí ìkẹ́kọ̀ọ́ dá lé” nínú ìwé Dáníẹ́lì, níbi táwọn ìpínrọ̀ tẹ́ ẹ jíròrò dá lé lórí.

* Ẹ sì tún lè ṣàtúnyẹ̀wò àwọn “ẹsẹ tí ìkẹ́kọ̀ọ́ dá lé,” ní ọ̀sẹ̀ tó ṣáájú, bí àyè bá ṣe wà sí.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́