ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 March ojú ìwé 6
  • March 27–April 2

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • March 27–April 2
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 March ojú ìwé 6

March 27–April 2

JEREMÁYÀ 12-16

  • Orin 135 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Pa Jèhófà Tì”: (10 min.)

    • Jer 13:​1-5​—Jeremáyà tẹ̀lé ìtọ́ni tí Jèhófà fún un pé kó tọ́jú ìgbànú aṣọ ọ̀gbọ̀ kan pa mọ́, àmọ́ iṣẹ́ yìí gba ìsapá gan-an (jr 51 ¶17)

    • Jer 13:​6, 7​—Nígbà tí Jeremáyà rìnrìn-àjò ọ̀nà jíjìn pa dà láti lọ mú ìgbànú náà, ó rí i pé ó ti bà jẹ́ (jr 52 ¶18)

    • Jer 13:​8-11​—Jèhófà fi èyí ṣàpẹẹrẹ pé àjọṣe tímọ́tímọ́ tó wà láàárín òun àtàwọn ọmọ Ísírẹ́lì máa bà jẹ́ torí pé wọ́n ya alágídí (jr 52 ¶19-20; it-1-E 1121 ¶2)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Jer 12:​1, 2, 14​—Ìbéèrè wo ni Jeremáyà béèrè, ìdáhùn wo sì ni Jèhófà fún un? (jr 118 ¶11)

    • Jer 15:17​—Kí ni ojú ìwòye Jeremáyà nípa yíyan ọ̀rẹ́, báwo la sì ṣe lè tẹ̀ lé àpẹẹrẹ rẹ̀? (w04 5/1 12 ¶16)

    • Ẹ̀kọ́ wo ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ mi nípa Jèhófà?

    • Àwọn kókó wo látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí ni mo lè lò lóde ẹ̀rí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Jer 13:​15-27

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ìwé ìkésíni síbi Ìrántí Ikú Kristi àti fídíò​—Jẹ́ kí onílé mọ̀ pé o máa pa dà wá.

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ìwé ìkésíni síbi Ìrántí Ikú Kristi àti fídíò​—Jẹ́ kí onílé mọ̀ pé o máa pa dà wá.

  • Àsọyé: (6 min.) w16.03 29-31​—Àkòrí: Ìgbà Wo Ni Bábílónì Ńlá Mú Àwọn Èèyàn Ọlọ́run Nígbèkùn?

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 139

  • “Ran Ìdílé Rẹ Lọ́wọ́ Kí Wọ́n Lè Máa Rántí Jèhófà”: (15 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará kọ́kọ́ wo fídíò náà ‘Kí Ọ̀rọ̀ Wọ̀nyí Wà ní Ọkàn Rẹ’​—Ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) kr orí 10 ¶8-11 àti àpótí ““Ibi Tí Kérésìmesì Ti Ṣẹ̀ Wá Àti Ìdí Tí Wọ́n Fi Ń Ṣe É”” àti “Àwọn Ayẹyẹ Mìíràn Tí Kò Bá Ìwé Mímọ́ Mu”

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 48 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́