2 SÁMÚẸ́LÌ
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
1
2
3
Ilé Dáfídì ń di alágbára sí i (1)
Àwọn ọmọkùnrin Dáfídì (2-5)
Ábínérì lọ dara pọ̀ mọ́ Dáfídì (6-21)
Jóábù pa Ábínérì (22-30)
Dáfídì ṣọ̀fọ̀ Ábínérì (31-39)
4
5
Dáfídì di ọba lórí gbogbo Ísírẹ́lì (1-5)
Wọ́n gba Jerúsálẹ́mù (6-16)
Dáfídì ṣẹ́gun àwọn Filísínì (17-25)
6
7
Dáfídì kò ní lè kọ́ tẹ́ńpìlì (1-7)
Ọlọ́run bá Dáfídì dá májẹ̀mú ìjọba (8-17)
Àdúrà ìdúpẹ́ tí Dáfídì gbà (18-29)
8
9
10
11
Dáfídì àti Bátí-ṣébà ṣe àgbèrè (1-13)
Dáfídì ṣètò pé kí wọ́n pa Ùráyà (14-25)
Dáfídì fi Bátí-ṣébà ṣe aya (26, 27)
12
Nátánì bá Dáfídì wí (1-15a)
Ọmọ Bátí-ṣébà kú (15b-23)
Bátí-ṣébà bí Sólómọ́nì (24, 25)
Dáfídì gba ìlú Rábà tó jẹ́ ti àwọn ọmọ Ámónì (26-31)
13
Ámínónì fipá bá Támárì lò pọ̀ (1-22)
Ábúsálómù pa Ámínónì (23-33)
Ábúsálómù sá lọ sí Géṣúrì (34-39)
14
Jóábù àti obìnrin ará Tèkóà (1-17)
Dáfídì já ọgbọ́nkọ́gbọ́n Jóábù (18-20)
Dáfídì gbà kí Ábúsálómù pa dà (21-33)
15
Ọ̀tẹ̀ àti rìkíṣí tí Ábúsálómù dì (1-12)
Dáfídì sá kúrò ní Jerúsálẹ́mù (13-30)
Áhítófẹ́lì dara pọ̀ mọ́ Ábúsálómù (31)
Ọba rán Húṣáì láti ta ko Áhítófẹ́lì (32-37)
16
Síbà sọ̀rọ̀ Méfíbóṣétì láìdáa (1-4)
Ṣíméì gbé Dáfídì ṣépè (5-14)
Ábúsálómù gba Húṣáì sọ́dọ̀ (15-19)
Ìmọ̀ràn Áhítófẹ́lì (20-23)
17
18
19
Dáfídì ṣọ̀fọ̀ Ábúsálómù (1-4)
Jóábù bá Dáfídì wí (5-8a)
Dáfídì pa dà sí Jerúsálẹ́mù (8b-15)
Ṣíméì tọrọ ìdáríjì (16-23)
Méfíbóṣétì fi hàn pé òun ò ṣẹ̀ (24-30)
Básíláì gbayì (31-40)
Àríyànjiyàn láàárín àwọn ẹ̀yà Ísírẹ́lì (41-43)
20
21
22
23
24