ÀÌSÁYÀ
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
1
Bàbá kan àti àwọn ọmọ rẹ̀ tó ya ọlọ̀tẹ̀ (1-9)
Jèhófà kórìíra ìjọsìn ojú lásán (10-17)
“Ẹ jẹ́ ká yanjú ọ̀rọ̀” (18-20)
Síónì máa pa dà di ìlú olóòótọ́ (21-31)
2
3
4
5
Orin nípa ọgbà àjàrà Jèhófà (1-7)
Ó mà ṣe fún ọgbà àjàrà Jèhófà o (8-24)
Ọlọ́run bínú sí àwọn èèyàn rẹ̀ (25-30)
6
Ìran nípa Jèhófà nínú tẹ́ńpìlì rẹ̀ (1-4)
A wẹ ètè Àìsáyà mọ́ (5-7)
Àìsáyà gba iṣẹ́ (8-10)
“Títí dìgbà wo, Jèhófà?” (11-13)
7
A ránṣẹ́ sí Ọba Áhásì (1-9)
Ohun tí a fi máa dá Ìmánúẹ́lì mọ̀ (10-17)
Ohun tó máa gbẹ̀yìn ìwà àìṣòótọ́ (18-25)
8
Ásíríà máa gbé ogun wá (1-8)
Ẹ má bẹ̀rù—“Ọlọ́run wà pẹ̀lú wa!” (9-17)
Àìsáyà àti àwọn ọmọ rẹ̀ máa jẹ́ àmì (18)
Ẹ yíjú sí òfin, kì í ṣe sí àwọn ẹ̀mí èṣù (19-22)
9
10
Ọwọ́ Ọlọ́run máa kọ lu Ísírẹ́lì (1-4)
Ásíríà—Ọ̀pá ìbínú Ọlọ́run (5-11)
Ìyà tó máa jẹ Ásíríà (12-19)
Àṣẹ́kù Jékọ́bù máa pa dà (20-27)
Ọlọ́run máa dá Ásíríà lẹ́jọ́ (28-34)
11
12
13
14
Ísírẹ́lì máa gbé ní ilẹ̀ tirẹ̀ (1, 2)
Wọ́n fi ọba Bábílónì ṣe ẹlẹ́yà (3-23)
Ọwọ́ Jèhófà máa fọ́ ará Ásíríà túútúú (24-27)
Ọ̀rọ̀ ìkéde sí Filísíà (28-32)
15
16
17
18
19
20
21
22
23
24
25
26
27
28
Ó mà ṣe fún àwọn ọ̀mùtípara Éfúrémù o! (1-6)
Àwọn àlùfáà àti wòlíì Júdà ń ta gọ̀ọ́gọ̀ọ́ (7-13)
Wọ́n “bá Ikú dá májẹ̀mú” (14-22)
Bí Jèhófà ṣe ń fi ọgbọ́n báni wí (23-29)
29
30
Íjíbítì ò lè ṣèrànwọ́ kankan (1-7)
Àwọn èèyàn ò fetí sí àsọtẹ́lẹ̀ (8-14)
Ìgbẹ́kẹ̀lé máa fi hàn pé wọ́n lágbára (15-17)
Jèhófà ṣojúure sí àwọn èèyàn rẹ̀ (18-26)
Jèhófà máa dá Ásíríà lẹ́jọ́ (27-33)
31
32
Ọba kan àti àwọn ìjòyè máa ṣàkóso fún ìdájọ́ òdodo (1-8)
A kìlọ̀ fún àwọn obìnrin tí ara tù (9-14)
Tí a bá tú ẹ̀mí jáde, ó máa mú ìbùkún wá (15-20)
33
34
35
36
37
Hẹsikáyà ní kí Àìsáyà bá òun bẹ Ọlọ́run fún ìrànlọ́wọ́ (1-7)
Senakérúbù halẹ̀ mọ́ Jerúsálẹ́mù (8-13)
Àdúrà tí Hẹsikáyà gbà (14-20)
Àìsáyà sọ ohun tí Ọlọ́run sọ (21-35)
Áńgẹ́lì kan pa 185,000 àwọn ọmọ Ásíríà (36-38)
38
39
40
41
Aṣẹ́gun kan láti ìlà oòrùn (1-7)
Ọlọ́run yan Ísírẹ́lì pé kó jẹ́ ìránṣẹ́ òun (8-20)
Ó pe àwọn ọlọ́run míì níjà (21-29)
42
Ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti ohun tó máa ṣe (1-9)
Orin ìyìn tuntun sí Jèhófà (10-17)
Ísírẹ́lì fọ́jú, ó sì dití (18-25)
43
Jèhófà pa dà kó àwọn èèyàn rẹ̀ jọ (1-7)
Kí àwọn ọlọ́run gbèjà ara wọn (8-13)
Wọ́n máa tú wọn sílẹ̀ láti Bábílónì (14-21)
“Jẹ́ ká gbé ẹjọ́ wa wá” (22-28)
44
Ọlọ́run máa bù kún àwọn àyànfẹ́ rẹ̀ (1-5)
Kò sí Ọlọ́run míì àfi Jèhófà (6-8)
Àwọn òrìṣà tí èèyàn ṣe kò já mọ́ nǹkan kan (9-20)
Jèhófà, Olùtúnrà Ísírẹ́lì (21-23)
Ipasẹ̀ Kírúsì ni wọ́n máa pa dà (24-28)
45
Ọlọ́run yan Kírúsì pé kó ṣẹ́gun Bábílónì (1-8)
Amọ̀ ò lè bá Amọ̀kòkò fà á (9-13)
Àwọn orílẹ̀-èdè míì mọ Ísírẹ́lì (14-17)
Ọlọ́run ṣeé gbára lé lórí ọ̀rọ̀ ìṣẹ̀dá àti ṣíṣí nǹkan payá (18-25)
46
47
48
Ọlọ́run bá Ísírẹ́lì wí, ó sì wẹ̀ ẹ́ mọ́ (1-11)
Jèhófà máa kọ lu Bábílónì (12-16a)
Ẹ̀kọ́ Ọlọ́run ṣàǹfààní (16b-19)
“Ẹ jáde kúrò ní Bábílónì!” (20-22)
49
50
51
52
53
54
55
56
57
Olódodo àti àwọn olóòótọ́ ṣègbé (1, 2)
Àgbèrè ẹ̀sìn tí Ísírẹ́lì ń ṣe hàn síta (3-13)
A tu àwọn ẹni rírẹlẹ̀ nínú (14-21)
58
59
Àwọn ẹ̀ṣẹ̀ Ísírẹ́lì mú kí wọ́n jìnnà sí Ọlọ́run (1-8)
Wọ́n jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ (9-15a)
Jèhófà dá sí i torí àwọn tó ronú pìwà dà (15b-21)
60
61
62
63
Jèhófà máa gbẹ̀san lára àwọn orílẹ̀-èdè (1-6)
Bí Jèhófà ṣe fi ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ hàn nígbà àtijọ́ (7-14)
Àdúrà ìrònúpìwàdà (15-19)
64
65
66
Ìjọsìn tòótọ́ àti ìjọsìn èké (1-6)
Síónì tó jẹ́ ìyá àti àwọn ọmọ rẹ̀ (7-17)
Àwọn èèyàn kóra jọ láti jọ́sìn ní Jerúsálẹ́mù (18-24)