ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 1587
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 2 Tímótì

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 2 Tímótì
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 2 Jòhánù
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Kí Ló Lè Ràn Wá Lọ́wọ́ Láti Fi Ọwọ́ Títọ̀nà Mú Òtítọ́?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2003
  • Fi Gbogbo Ọkàn Rẹ sí Iṣẹ́ Ìsìn Rẹ!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2020
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 2 Tẹsalóníkà
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 2 Tímótì

2 TÍMÓTÌ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Ìkíni (1, 2)

    • Pọ́ọ̀lù dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run torí ìgbàgbọ́ Tímótì (3-5)

    • Jẹ́ kí ẹ̀bùn Ọlọ́run máa jó bí iná (6-11)

    • Máa tẹ̀ lé àwọn ọ̀rọ̀ tó ṣàǹfààní (12-14)

    • Àwọn ọ̀tá Pọ́ọ̀lù àtàwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ (15-18)

  • 2

    • Fi ọ̀rọ̀ náà síkàáwọ́ àwọn ọkùnrin tó kúnjú ìwọ̀n (1-7)

    • Jìyà nítorí ìhìn rere (8-13)

    • Máa lo ọ̀rọ̀ Ọlọ́run bó ṣe yẹ (14-19)

    • Sá fún àwọn ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ìgbà ọ̀dọ́ (20-22)

    • Ohun tí o lè ṣe sí àwọn alátakò (23-26)

  • 3

    • Nǹkan máa le gan-an ní àwọn ọjọ́ ìkẹyìn (1-7)

    • Tẹ̀ lé àpẹẹrẹ Pọ́ọ̀lù pẹ́kípẹ́kí (8-13)

    • “Má ṣe fi àwọn nǹkan tí o ti kọ́ sílẹ̀” (14-17)

      • Gbogbo Ìwé Mímọ́ ni Ọlọ́run mí sí (16)

  • 4

    • “Ṣe iṣẹ́ òjíṣẹ́ rẹ láìkù síbì kan” (1-5)

      • Wàásù ọ̀rọ̀ náà láìfi falẹ̀ (2)

    • “Mo ti ja ìjà rere náà” (6-8)

    • Àwọn ọ̀rọ̀ ara ẹni (9-18)

    • Ìkíni tó fi parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ (19-22)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́