ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 1615
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 1 Pétérù

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 1 Pétérù
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Róòmù
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 2 Jòhánù
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Ẹ̀yin Aya, Ẹ Ní Ọ̀wọ̀ Jíjinlẹ̀ Fún Ọkọ Yín
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2007
  • Ẹ Kó Gbogbo Àníyàn Yín Lé Jehofa
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1994
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 1 Pétérù

1 PÉTÉRÙ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Ìkíni (1, 2)

    • Ìbí tuntun tó jẹ́ ká lè ní ìrètí tó wà láàyè (3-12)

    • Ẹ jẹ́ mímọ́ bí ọmọ tó ń ṣègbọràn (13-25)

  • 2

    • Kí ọ̀rọ̀ náà máa wù yín (1-3)

    • Òkúta ààyè tí a fi kọ́ ilé tẹ̀mí (4-10)

    • Ẹ máa gbé bí àjèjì nínú ayé (11, 12)

    • Àwọn tó yẹ ká tẹrí ba fún (13-25)

      • Kristi fi àpẹẹrẹ lélẹ̀ fún wa (21)

  • 3

    • Àwọn ọkọ àti àwọn aya (1-7)

    • Ẹ máa bára yín kẹ́dùn; ẹ máa wá àlàáfíà (8-12)

    • Tí a bá ń jìyà nítorí òdodo (13-22)

      • Ẹ ṣe tán láti gbèjà ìrètí yín (15)

      • Ìrìbọmi àti ẹ̀rí ọkàn rere (21)

  • 4

    • Ẹ ṣe ìfẹ́ Ọlọ́run bíi ti Kristi (1-6)

    • Òpin ohun gbogbo ti sún mọ́lé (7-11)

    • Tí a bá ń jìyà torí pé a jẹ́ Kristẹni (12-19)

  • 5

    • Ẹ máa ṣe olùṣọ́ àgùntàn agbo Ọlọ́run (1-4)

    • Ẹ jẹ́ onírẹ̀lẹ̀, kí ẹ sì wà lójúfò (5-11)

      • Ẹ máa kó gbogbo àníyàn yín lé Ọlọ́run (7)

      • Èṣù dà bíi kìnnìún tó ń ké ramúramù (8)

    • Ọ̀rọ̀ ìparí (12-14)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́