ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • g 1/10 ojú ìwé 31
  • Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?
  • Jí!—2010
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Kí Ni Kò Tọ̀nà Nínú Àwòrán Yìí?
  • Nínú Ìtẹ̀jáde Yìí
  • Kí Lo Mọ̀ Nípa Jẹ́fútà Onídàájọ́?
  • ÌDÁHÙN SÍ ÌBÉÈRÈ
  • Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?
    Jí!—2009
  • Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?
    Jí!—2008
  • Àtúnyẹ̀wò fún Ìdílé
    Jí!—2010
  • Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?
    Jí!—2009
Àwọn Míì
Jí!—2010
g 1/10 ojú ìwé 31

Kí Ni Ìdáhùn Rẹ?

Kí Ni Kò Tọ̀nà Nínú Àwòrán Yìí?

Ka Ìṣe 8:26-40. Wo àwòrán yìí. Àwọn nǹkan wo ni kò tọ̀nà nínú àwòrán náà? Kọ ìdáhùn rẹ sórí àwọn ìlà yìí.

1. ․․․․․

2. ․․․․․

3. ․․․․․

FÚN ÌJÍRÒRÒ:

Kí nìdí tí ìwẹ̀fà yẹn kò fi lóye ohun tó ń kà? Ta ló ràn án lọ́wọ́ tó fi lóye ohun tó ń kà? Àwọn ọ̀nà wo lo lè gbà fara wé ìwẹ̀fà yẹn?

Nínú Ìtẹ̀jáde Yìí

Dáhùn àwọn ìbéèrè yìí, kó o sì kọ (àwọn) ẹsẹ Bíbélì tó yẹ sínú àlàfo.

OJÚ ÌWÉ 3 Ẹni tí kò bá pèsè fún ìdílé rẹ̀ burú ju ta ni lọ? 1 Tímótì 5:․․․

OJÚ ÌWÉ 16 Bó bá dọ̀rọ̀ ìrísí wa, kí ló yẹ ká fi sọ́kàn? 1 Pétérù 3:․․․

OJÚ ÌWÉ 24 Bí ebi bá ń pa ọ̀tá rẹ kí ló yẹ kó o ṣe? Róòmù 12:․․․

OJÚ ÌWÉ 27 Ká bàa lè máa láyọ̀, kí ló gbọ́dọ̀ máa jẹ wá lọ́kàn? Mátíù 5:․․․

Kí Lo Mọ̀ Nípa Jẹ́fútà Onídàájọ́?

Ka Àwọn Onídàájọ́ 11:1–12:7. Dáhùn àwọn ìbéèrè wọ̀nyí.

4. ․․․․․

Èwo lára ẹ̀yà Ísírẹ́lì méjìlá ló ti wá?

AMỌ̀NÀ: Wo Númérì 26:29.

5. ․․․․․

Ọwọ́ orílẹ̀-èdè wo ló ti gba àwọn ọmọ Ísírẹ́lì sílẹ̀?

6. ․․․․․

Bẹ́ẹ̀ ni tàbí rárá? Ó gbé ayé lẹ́yìn Jósẹ́fù, ọmọkùnrin Jákọ́bù (Ísírẹ́lì).

FÚN ÌJÍRÒRÒ:

Kí lo rò pé ó mú kí ọmọbìnrin Jẹ́fútà fọwọ́ sowọ́ pọ̀ kí bàbá rẹ̀ lè mú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ ṣẹ? Báwo lo ṣe lè tẹ̀ lé àpẹẹrẹ ọmọbìnrin Jẹ́fútà?

ÌDÁHÙN SÍ ÌBÉÈRÈ

1. Ó jọ pé Fílípì nìkan ló dá wà.

2. Kẹ̀kẹ́ ẹṣin ni ìwẹ̀fà yẹn gùn kì í ṣe ẹṣin.

3. Aṣálẹ̀ ni ìṣẹ̀lẹ̀ yẹn ti wáyé kì í ṣe àárín ìlú téèyàn pọ̀ sí.

4. Mánásè.—Númérì 26:29; Àwọn Onídàájọ́ 11:1.

5. Ámónì—Àwọn Onídàájọ́ 11:4.

6. Òótọ́.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́