ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sn orin 3
  • “Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”
  • Kọrin sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • “Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Bá a Ṣe Lè Nífẹ̀ẹ́ Ọmọnìkejì Wa
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2006
  • ‘Ẹ Máa Rìn Nínú Ìfẹ́’
    Sún Mọ́ Jèhófà
  • Nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́run Tó Nífẹ̀ẹ́ Rẹ
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2006
Àwọn Míì
Kọrin sí Jèhófà
sn orin 3

Orin 3

“Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”

Bíi Ti Orí Ìwé

(1 Jòhánù 4:7, 8)

1. Ọlọ́run ìfẹ́ ńpè wá pé,

‘Bá mi rìn, fẹ́ ọ̀nà mi.’

Báa nífẹ̀ẹ́ Jáà àti èèyàn,

Ire ṣáá la ó máa ṣe.

Ìgbé ayé ire nìyẹn;

Ìgbé ayé tí a ńfẹ́.

Ìfẹ́ bíi Kristi kìí kùnà.

Ìfẹ́ yìí yóò sì máa hàn.

2. Ìfẹ́ òtítọ́ ńdarí wa;

Ìfẹ́ Jáà ńmú wa nífẹ̀ẹ́.

Táa bá ṣubú òun yóò gbé wa;

Okun rẹ̀ laó fi dìde.

Mímọ́ nìfẹ́ kìí sìí jowú;

Ó nínúure òun sùúrù.

Ká ní ìfẹ́ àwọn ará.

Ká jadùn ìfẹ́ tòótọ́.

3. Má fàyè gba ìkórìíra;

Má ṣe jẹ́ kó sún mọ́ ọ.

Wo Jáà yóò sì tọ́ ọ sọ́nà;

Yóò kọ́ ọ ní àṣẹ yìí:

Nífẹ̀ẹ́ Jèhófà àtèèyàn,

Mọ bí ìfẹ́ ṣe jẹ́ gan-an.

Ká nífẹ̀ẹ́ ọmọnìkejì,

Ìfẹ́ jẹ̀lẹ́ńkẹ́ sì ni.

(Tún wo Máàkù 12:30, 31; 1 Kọ́r. 12:31–13:8; 1 Jòh. 3:23.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́