Ọ̀rọ̀ Ìṣáájú
KÍ LÈRÒ RẸ?
Ṣé Ọlọ́run fẹ́ ká máa kú? Bíbélì sọ pé: “[Ọlọ́run] yóò sì nu omijé gbogbo nù kúrò ní ojú wọn, ikú kì yóò sì sí mọ́.”—Ìṣípayá 21:4.
Ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́ yìí ṣàlàyé ohun tí Bíbélì sọ nípa ìyè àti ikú.
Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.
Má bínú, fídíò yìí kò jáde.
Ṣé Ọlọ́run fẹ́ ká máa kú? Bíbélì sọ pé: “[Ọlọ́run] yóò sì nu omijé gbogbo nù kúrò ní ojú wọn, ikú kì yóò sì sí mọ́.”—Ìṣípayá 21:4.
Ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́ yìí ṣàlàyé ohun tí Bíbélì sọ nípa ìyè àti ikú.