ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb16 May ojú ìwé 7
  • Bẹ Jèhófà Pé Kó Jẹ́ Kó O Ní Ìgboyà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Bẹ Jèhófà Pé Kó Jẹ́ Kó O Ní Ìgboyà
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Dáfídì Kò Bẹ̀rù
    Kọ́ Ọmọ Rẹ
  • “Ti Jèhófà Ni Ìjà Ogun Náà”
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde)—2016
  • “Kọ́ Mi Láti Máa Ṣe Ìfẹ́ Rẹ”
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2012
  • “Jẹ́ Onígboyà . . . Kí O sì Gbé Ìgbésẹ̀”
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2017
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
mwb16 May ojú ìwé 7

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | SÁÀMÙ 26-33

Bẹ Jèhófà Pé Kó Jẹ́ Kó O Ní Ìgboyà

Dáfídì túbọ̀ ní ìgboyà nígbà tó rántí bí Jèhófà ṣe gbà á sílẹ̀ láwọn ìgbà kan

27:1-3

  • Jèhófà gba Dáfídì sílẹ̀ lọ́wọ́ kìnnìún nígbà tó wà lọ́mọdé

  • Jèhófà jẹ́ kí Dáfídì pa béárì kan kó lè dáàbò bo agbo ẹran rẹ̀

  • Jèhófà ti Dáfídì lẹ́yìn nígbà tó pa Gòláyátì

Dáfídì ń rántí bí Jèhófà ṣe gbà á sílẹ̀ lọ́wọ́ kìnnìún, bó ṣe jẹ́ kó pa béárì kan àti bó ṣe tì í lẹ́yìn nígbà tó pa Gòláyátì

Kí ló máa jẹ́ ká ní ìgboyà bíi ti Dáfídì?

27:4, 7, 11

  • Àdúrà

  • Iṣẹ́ ìwàásù

  • Lílọ sí ìpàdé

  • Ìdákẹ́kọ̀ọ́ àti ìjọsìn ìdílé

  • Fífún àwọn ẹlòmíì níṣìírí

  • Ká máa rántí bí Jèhófà ṣe ràn wá lọ́wọ́ láwọn ìgbà kan

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́