ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb16 July ojú ìwé 3
  • Ẹ Yin Jèhófà, Olùgbọ́ Àdúrà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ẹ Yin Jèhófà, Olùgbọ́ Àdúrà
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Sún Mọ́ Ọlọ́run Nípasẹ̀ Àdúrà
    Kí Ni Bíbélì Fi Kọ́ni Gan-an?
  • Ẹ Máa Gbé Ọwọ́ Ìdúróṣinṣin Sókè Nínú Àdúrà
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1999
  • Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Máa Gbàdúrà Láìdabọ̀?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2003
  • Máa Gbàdúrà Kó O Lè Rí Ojú Rere Ọlọ́run
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde)—2020
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
mwb16 July ojú ìwé 3

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | SÁÀMÙ 60-68

Ẹ Yin Jèhófà, Olùgbọ́ Àdúrà

Tó o bá ṣèlérí fún Jèhófà, máa bẹ̀ ẹ́ pé kó ràn ẹ́ lọ́wọ́ kó o lè mú ìlérí rẹ ṣẹ

61:1, 8

  • Tó o bá ń gbàdúrà nípa àwọn ìlérí tó o ṣe, Jèhófà á fún ẹ lókun kó o lè mú un ṣẹ

  • Bí a ṣe ya ara wa sí mímọ́ fún Ọlọ́run ni ìlérí tó ṣe pàtàkì jù lọ tá a ṣe

Hánà ń gbàdúrà

Hánà

Tó o bá sọ gbogbo ohun tó wà lọ́kàn rẹ fún Jèhófà, ìyẹn á fi hàn pé o gbẹ́kẹ̀ lé e

62:8

  • Kí àdúrà wa lè nítumọ̀, a ní láti máa sọ gbogbo bí nǹkan ṣe rí lára wa fún Jèhófà

  • Tí àdúrà wa bá ṣe pàtó, ìdáhùn Jèhófà sí àdúrà wa á ṣe kedere sí wa

Jésù ń gbàdúrà

Jésù

Jèhófà ni Olùgbọ́ àdúrà gbogbo àwọn tó lọ́kàn rere

65:1, 2

  • Jèhófà máa ń tẹ́tí sí “àwọn ènìyàn ẹlẹ́ran ara gbogbo” tó fẹ́ mọ̀ ọ́n, tí wọ́n sì fẹ́ fi tọkàntọkàn ṣe ìfẹ́ rẹ̀

  • Ìgbàkigbà la lè gbàdúrà sí Jèhófà

Kọ̀nílíù ń gbàdúrà

Kọ̀nílíù

Àwọn nǹkan tí mo fẹ́ fi sínú àdúrà mi.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́