ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb16 October ojú ìwé 3
  • “Má Ṣe Jẹ́ Kí Ọkàn-Àyà Rẹ Yà Bàrá”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Má Ṣe Jẹ́ Kí Ọkàn-Àyà Rẹ Yà Bàrá”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Báwo Lo Ṣe Lè Dáàbò Bo Ọkàn Rẹ?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2019
  • Ṣọ́ra! Sátánì Fẹ́ Pa Ọ́ Jẹ
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2015
  • Ní Ọkàn-àyà Tó Tẹ́ Jèhófà Lọ́rùn
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2001
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Yìí
    Jí!—2022
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
mwb16 October ojú ìwé 3

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | ÒWE 7-11

“Má Ṣe Jẹ́ Kí Ọkàn-àyà Rẹ Yà Bàrá”

Ọ̀dọ́kùnrin kan ń wo ilé obìnrin oníṣekúṣe kan lọ́ọ̀ọ́kán

Àwọn ìlànà Jèhófà máa ń dáàbò bò wá. Àmọ́, kí wọ́n tó lè ṣe wá láǹfààní, a gbọ́dọ̀ fi wọ́n sínú ọkàn wa. (Owe 7:⁠3) Ṣùgbọ́n bí ìránṣẹ́ Jèhófà èyíkéyìí bá lọ jẹ́ kí ọkàn òun yà bàrá, wẹ́rẹ́ ló máa kó sọ́wọ́ àwọn ètekéte Sátánì. Òwe orí 7 ṣàpèjúwe ọ̀dọ́kùnrin kan tó jẹ́ kí ọkàn rẹ̀ tàn án jẹ. Kí la lè rí kọ́ nínú àṣìṣe tó ṣe?

  • Ojú

    Ìríran

    7:10

  • Obìnrin kan fọwọ́ kan apá ọkùnrin kan

    Ìmọ̀lára

    7:13

  • Búrẹ́dì àti wáìnì

    Ìtọ́wò

    7:14

  • Ìgò lọ́fíńdà

    Ìgbóòórùn

    7:17

  • Obìnrin kan ń sọ̀rọ̀ sí ọkùnrin kan létí

    Ìgbọ́rọ̀

    7:21

  • Sátánì ń gbìyànjú ká lè ṣi àwọn ẹ̀yà ara márààrún tó wà fún ìmòye lò, ká lè tipa bẹ́ẹ̀ hùwà àìtọ́

  • Ọgbọ́n àti òye ló máa ràn wá lọ́wọ́ láti ronú lórí àbájáde ohun tá a fẹ́ ṣe, ká lè sá fún ohun tó lè ba àjọṣe wa pẹ̀lú Ọlọ́run jẹ́

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́