ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 August ojú ìwé 3
  • Jèhófà San Ìlú Abọ̀rìṣà Kan Lẹ́san

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Jèhófà San Ìlú Abọ̀rìṣà Kan Lẹ́san
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Jèhófà Máa Ń Sẹ̀san fún Àwọn Tó Ń Fi Taratara Wá A
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2016
  • Jèhófà Sọ Ìyangàn Tírè Di Ẹ̀tẹ́
    Àsọtẹ́lẹ̀ Aísáyà—Ìmọ́lẹ̀ fún Gbogbo Aráyé, Apá Kìíní
  • Àsọtẹ́lẹ̀ Nípa Bí Ìlú Tírè Ṣe Máa Pa Run Mú Ká Fọkàn Tán Ọ̀rọ̀ Jèhófà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Ǹjẹ́ O Mọ̀?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 August ojú ìwé 3

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | ÌSÍKÍẸ́LÌ 28-31

Jèhófà San Ìlú Abọ̀rìṣà Kan Lẹ́san

29:18-20

Bí Jèhófà bá lè san ìlú abọ̀rìṣà lẹ́san fún iṣẹ́ tó ṣe, ó dájú pé ó máa san àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ olóòótọ́ lẹ́san fún iṣẹ́ tí wọ́n ṣe!

OHUN TÍ BÁBÍLÓNÌ ṢE

Wọ́n sàga ti ìlú Tírè

Àwọn ọmọ ogun Bábílónì sàga ti ìlú Tírè

OHUN TÍ MÀÁ ṢE

Irú ogun tẹ̀mí wo ni mò ń jà?

OHUN TÍ OJÚ ÀWỌN ARÁ BÁBÍLÓNÌ RÍ

  • Lára ohun tí ojú àwọn ará Bábílónì rí ni pé ọdún mẹ́tàlá ni wọ́n fi sàga ti ìlú Tírè, owó kékeré kọ́ nìyẹn sì ná wọn

    Ọdún mẹ́tàlá ni wọ́n fi sàga ti ìlú Tírè, owó kékeré kọ́ nìyẹn sì ná wọn

  • Lára ohun tí ojú àwọn ará Bábílónì rí ni pé àwọn ọmọ ogun wọn jìyà

    Àwọn ọmọ ogun Bábílónì jìyà

  • Lára ohun tí ojú àwọn ará Bábílónì rí ni pé wọn kò rí owó kankan gbà

    Àwọn ará Bábílónì kò rí owó kankan gbà

ÀWỌN NǸKAN TÍ MO YÁÁFÌ

Àwọn nǹkan wo ni mo ti yááfì lẹ́nu iṣẹ́ ìsìn mi sí Jèhófà?

BÍ JÈHÓFÀ ṢE SAN BÁBÍLÓNÌ LẸ́SAN

Jèhófà fi Íjíbítì lé wọn lọ́wọ́ gẹ́gẹ́ bí ohun ìfiṣèjẹ

Àpótí ìṣura

BÍ JÈHÓFÀ ṢE SAN MÍ LẸ́SAN

Báwo ni Jèhófà ṣe san mí lẹ́san?

Kọ àwọn ẹsẹ Bíbélì tó yẹ sí iwájú àwọn ọ̀rọ̀ yìi.

  • Rut 2:12

  • Mal 3:16

  • Heb 6:10

  • “Olọ́run kì í ṣe aláìṣòdodo tí yóò fi gbàgbé iṣẹ́ yín àti ìfẹ́ tí ẹ fi hàn fún orúkọ rẹ̀.”

  • “Kí Jèhófà san ọ́ lẹ́san fún bí o ṣe hùwà, kí owó ọ̀yà pípé sì wà fún ọ láti ọ̀dọ̀ Jèhófà.”

  • “Ìwé ìrántí kan ni a sì bẹ̀rẹ̀ sí kọ sílẹ̀ níwájú rẹ̀ fún àwọn tí ó bẹ̀rù Jèhófà àti fún àwọn tí ń ronú lórí orúkọ rẹ̀.”

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́