ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 September ojú ìwé 6
  • Wọ́n Mú Ọrẹ Wá fún Jèhófà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Wọ́n Mú Ọrẹ Wá fún Jèhófà
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Eka To N Yaworan To si N Kole Kari Aye
    Ìwé Ọdọọdún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà—2015
  • Àwọn Ilé Tá À Ń Kọ́ Ń Bọlá fún Jèhófà
    Ìjọba Ọlọ́run Ti Ń Ṣàkóso!
  • Ibi Ìjọsìn Wa Rèé
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2015
  • Ìbísí Bíbùáyà Mú Kí Ìmúgbòòrò Ojú Ẹsẹ̀ Pọn Dandan
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2002
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 September ojú ìwé 6
Arákùnrin kan ń fowó sínú àpótí ọrẹ.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | Ẹ́KÍSÓDÙ 29-30

Wọ́n Mú Ọrẹ Wá fún Jèhófà

30:11-16

Nígbà táwọn ọmọ Ísírẹ́lì ń kọ́ àgọ́ ìjọsìn, àtolówó àti tálákà ló láǹfààní láti mú ọrẹ wá fún iṣẹ́ náà. Báwo làwa náà ṣe lè mú ọrẹ wá fún Jèhófà lónìí? Ọ̀nà kan ni pé ká máa fi owó sínú àpótí ní Gbọ̀ngàn Ìjọba, Gbọ̀ngàn Àpéjọ, ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè, Bẹ́tẹ́lì àtàwọn ilé míì tá a yà sí mímọ́ fún ìjọsìn Jèhófà.

Ẹ̀kọ́ wo la rí kọ́ nínú àwọn ẹsẹ Bíbélì yìí tó bá dọ̀rọ̀ ká máa fi owó ṣètọrẹ fún ìjọsìn mímọ́?

  • 1Kr 29:5

  • Mk 12:43, 44

  • 1Kọ 16:2

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́