ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb21 March ojú ìwé 4
  • Kí Nìdí Tí Kò Fi Yẹ Ká Máa Ráhùn?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Kí Nìdí Tí Kò Fi Yẹ Ká Máa Ráhùn?
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Idi Ti Ìpín Aláròyé kìí Fií Ṣe Ọ̀kan Ti Ó Jẹ́ Alayọ
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1993
  • Ǹjẹ́ Gbogbo Àròyé ni Ó Burú?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1997
  • Jèhófà Sọ Ègún Di Ìbùkún
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Ẹnì Kan Lè Ṣe Ọ̀pọ̀ Èèyàn Láǹfààní
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
mwb21 March ojú ìwé 4
Inú arábìnrin kan ò dùn, ó wá káwọ́ gbera, kò sì dá sáwọn tó kù nínú Gbọ̀ngàn Ìjọba.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Kí Nìdí Tí Kò Fi Yẹ Ká Máa Ráhùn?

Inú Jèhófà kì í dùn sáwọn tó bá ń ráhùn (Nọ 11:1; w01 6/15 17 ¶20)

Aláìmoore àti onímọ̀-tara-ẹni-nìkan lẹni tó bá ń ráhùn (Nọ 11:​4-6; w06 7/15 15 ¶7)

Tá a bá ń ráhùn, ó lè jẹ́ kí nǹkan sú àwọn míì (Nọ 11:​10-15; it-2 719 ¶4)

Nǹkan ò rọrùn fáwọn ọmọ Ísírẹ́lì nínú aginjù lóòótọ́, síbẹ̀ ó yẹ kí wọ́n máa dúpẹ́ torí ọ̀pọ̀ nǹkan ni Jèhófà ti ṣe fún wọn. Táwa náà bá ń fara balẹ̀ ronú lórí ọ̀pọ̀ nǹkan tí Jèhófà ti ṣe fún wa, a ò ní máa ráhùn.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́