ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb21 March ojú ìwé 12
  • Jèhófà Sọ Ègún Di Ìbùkún

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Jèhófà Sọ Ègún Di Ìbùkún
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Iṣẹ́ Ìsìn Àwọn Ọmọ Léfì
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Ohun Tá A Rí Kọ́ Látinú Bí Jèhófà Ṣe Ṣètò Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Bí Jèhófà Ṣe Ń Darí Àwọn Èèyàn Rẹ̀
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Kí Nìdí Tí Kò Fi Yẹ Ká Máa Ráhùn?
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
mwb21 March ojú ìwé 12
Àwọn arábìnrin méjì ń wàásù fún obìnrin tó ń palẹ̀ ìdọ̀tí ilé ẹ̀ mọ́ lẹ́yìn tí àjálù ṣẹlẹ̀.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Jèhófà Sọ Ègún Di Ìbùkún

Àwọn ọmọ Móábù ń wá bí wọ́n ṣe máa hùwà ìkà sáwọn ọmọ Ísírẹ́lì (Nọ 22:​3-6)

Jèhófà gbèjà àwọn èèyàn rẹ̀ (Nọ 22:​12, 34, 35; 23:​11, 12)

Kò sẹ́ni tó lè gbéjà ko Jèhófà kó sì ṣàṣeyọrí (Nọ 24:​12, 13; bt 53 ¶5; it-2 291)

Ìfẹ́ Ọlọ́run ni pé ká wàásù ìhìn rere, kò sì sí ohunkóhun tó lè dí i lọ́wọ́, títí kan inúnibíni tàbí àjálù. Ṣé a máa ń gbára lé Baba wa ọ̀run, tá a sì ń fi ìjọsìn rẹ̀ sípò àkọ́kọ́, kódà nígbà tí nǹkan ò bá rọrùn fún wa?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́