ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb21 September ojú ìwé 14
  • Dáàbò Bo Ogún Iyebíye Tí Jèhófà Fún Ẹ

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Dáàbò Bo Ogún Iyebíye Tí Jèhófà Fún Ẹ
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Jèhófà Fọgbọ́n Pín Ilẹ̀ Fáwọn Èèyàn Rẹ̀
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Jèhófà Jà Fáwọn Ọmọ Ísírẹ́lì
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Ìmọ̀ràn Tí Jóṣúà Fún Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Kẹ́yìn
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Jèhófà Fẹ́ Káwọn Èèyàn Rẹ̀ Yàtọ̀
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
mwb21 September ojú ìwé 14

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Dáàbò Bo Ogún Iyebíye Tí Jèhófà Fún Ẹ

Kélẹ́bù lé àwọn ọ̀tá kúrò lórí ilẹ̀ tí Jèhófà fún un, ó sì tipa bẹ́ẹ̀ dáàbò bo ilẹ̀ náà (Joṣ 15:14; it-1 1083 ¶3)

Kì í ṣe gbogbo àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ló lé àwọn tí kì í ṣe olùjọsìn Jèhófà kúrò lórí ilẹ̀ wọn (Joṣ 16:10; it-1 848)

Jèhófà máa ń ṣèrànwọ́ fáwọn tó bá pinnu láti dáàbò bo ogún wọn (Di 20:1-4; Joṣ 17:17, 18; it-1 402 ¶3)

Jèhófà ṣèlérí láti fún gbogbo àwọn tó jẹ́ olóòótọ́ ní ẹ̀bùn iyebíye kan, ìyẹn ìyè àìnípẹ̀kun. Ká lè dáàbò bo ogún yìí, à ń sapá láti borí àwọn ìdẹwò Sátánì. Ìdí nìyẹn tá a fi ń kẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì lójoojúmọ́, tá à ń lọ sípàdé déédéé, tá à ń ṣiṣẹ́ ìwàásù, tá a sì ń gbàdúrà.

Bàbá kan ń ṣe ìjọsìn ìdílé pẹ̀lú ìyàwó àtàwọn ọmọ rẹ̀.

BI ARA RẸ PÉ, ‘Ṣé mò ń dáàbò bo ogún iyebíye tí Jèhófà fún mi?’

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́