ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb23 September ojú ìwé 9
  • Ṣọ́ra Fáwọn Ọ̀rọ̀ Tí Kì Í Ṣòótọ́

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ṣọ́ra Fáwọn Ọ̀rọ̀ Tí Kì Í Ṣòótọ́
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Má Ṣe Sọ̀rọ̀ Bíi Élífásì Tó O Bá Ń Tu Àwọn Èèyàn Nínú
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Má Ṣe Fàyè Gba Èrò Òdì!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • “Mi Ò Ní Fi Ìwà Títọ́ Mi Sílẹ̀!”
    Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Ìgbàgbọ́ Wọn
  • Jobu Lo Ìfaradà—Àwa Pẹ̀lú Lè Ṣe Bẹ́ẹ̀!
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1994
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
mwb23 September ojú ìwé 9

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Ṣọ́ra Fáwọn Ọ̀rọ̀ Tí Kì Í Ṣòótọ́

Torí pé àgbàlagbà ni Élífásì, ó sì gbọ́n, ọ̀pọ̀ èèyàn gbà pé ọ̀rọ̀ tó bá sọ máa ṣeé gbára lé (Job 4:1; it-1 713 ¶11)

Àwọn ẹ̀mí èṣù mú kí Élífásì sọ ọ̀rọ̀ tó máa kó ìrẹ̀wẹ̀sì bá Jóòbù (Job 4:​14-16; w05 9/15 26 ¶2)

Bó tiẹ̀ jẹ́ pé òótọ́ díẹ̀ wà nínú ọ̀rọ̀ tí Élífásì sọ, àmọ́ ìtumọ̀ míì ló fún un (Job 4:19; w10 2/15 19 ¶5-6)

Arákùnrin kan ń wo fóònù rẹ̀.

Nínú ayé tí Sátánì ń ṣàkóso yìí, àwọn èèyàn máa ń tan àwọn ọ̀rọ̀ tí kì í ṣòótọ́ kálẹ̀.

BI ARA RẸ PÉ, ‘Ṣé mo máa ń fara balẹ̀ ronú lórí ohun tí mo bá gbọ́ kí n lè mọ̀ bóyá ó jóòótọ́?’—mrt 32 ¶13-17.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́